Publicidade

Lucas 17

̀ṣẹ̀, ìgbàgbọ́, àti iṣẹ́

1 17.1-2: Mt 18.6-7; Mk 9.42; 1Kọ 8.12. Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "le ṣe ohun ìkọ̀sẹ̀ máa wa, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ẹni ó ti ipasẹ̀ rẹ̀ . 2 Ìbá sàn fún un a so ọlọ mọ́ ọn ọrùn, a gbé e sínú Òkun, ju ó ̀kan nínú àwọn kékeré wọ̀nyí kọsẹ̀. 3 17.3-4: Mt 18.15,21-22.máa kíyèsára yín.

"arákùnrin rẹ ṣẹ̀, a ; ó ronúpìwàdà, dáríjì ín. 4 ó ṣẹ̀ ́ igba méje òòjọ́, ó padà tọ̀ ́ ìgbà méje òòjọ́ , Mo ronúpìwàdà,dáríjì ín."

5 17.5-6: Mt 17.20; 21.21; Mk 11.22-23. 17.5: Lk 7.13. Àwọn aposteli fún Olúwa , "ìgbàgbọ́ wa."

6 Olúwa , "̀yin ìgbàgbọ́ hóró irúgbìn musitadi, ̀yin yóò fún igi sikamine yìí , Di fi á tu, a gbìn ́ sínú Òkun,yóò gbọ́ tiyín.

7 "Ṣùgbọ́n ta ni nínú yín, ó ọmọ ̀dọ̀, ó ń tulẹ̀, tàbí ó ń bọ́ ẹran, yóò fún un lójúkan náà ó ti oko , Lọ í jókòó láti jẹun? 8 17.8: Lk 12.37; Jh 13.3-5.yóò kúkú fún un , Pèsè ohun èmi yóò jẹ, di àmùrè, ìwọ ó máa ṣe ìránṣẹ́ fún mi, títí èmi ó fi jẹ èmi ó mu tán; lẹ́yìn náà ni ìwọ ó jẹ, ìwọ ó mu? 9 Òun ó ha máa ọpẹ́ lọ́wọ́ ọmọ ̀dọ̀ náà, nítorí ó ṣe ohun a pàṣẹ fún un ? Èmi bẹ́̀. 10 Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ̀yin pẹ̀, nígbà ti ṣe ohun gbogbo a pàṣẹ fún yín tán, , Aláìlérè ọmọ ̀dọ̀ ni : èyí í ṣe iṣẹ́ wa láti ṣe, àwa ti ṣe.’ "

Ìwòsàn adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá

11 17.11: Lk 9.51; 13.22; 19.11. Ó ṣe, ó ti ń lọ Jerusalẹmu, ó kọjá láàrín Samaria Galili. 12 17.12: Le 13.45-46.ó ti ń wọ inú ìletò kan lọ, àwọn ọkùnrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá pàdé rẹ̀, wọ́n dúró òkèrè, 13 17.13: Lk 5.5; 8.24,45; 9.33,49.wọ́n kígbe sókè , "Jesu, Olùkọ́, ṣàánú fún wa."

14 17.14: Lk 5.14; Mt 8.4; Mk 1.44; Le 14.2-32. Nígbà ó wọn, ó fún wọn , "lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà." Ó ṣe, wọ́n ti ń lọ, wọ́n di mímọ́.

15 Nígbà ̀kan nínú wọn i a òun láradá ó padà, ó fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo. 16 Ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.

17 Jesu dáhùn , "Àwọn mẹ́wàá a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha ? 18 A ẹnìkan ó padà fi ògo fún Ọlọ́run, ṣe àlejò yìí?" 19 17.19: Mt 9.22; Mk 5.34; Lk 8.48; 18.42.Ó fún un , "Dìde, o máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ láradá."

Bíbọ̀ ìjọba Ọlọ́run

20 17.20: Lk 19.11; 21.7; Ap 1.6. Nígbà àwọn Farisi bi í , nígbà wo ni ìjọba Ọlọ́run yóò , ó wọn lóhùn , "Ìjọba Ọlọ́run í pẹ̀àmì. 21 Bẹ́̀ ni wọn yóò , Kíyèsi i níhìn-ín!tàbí Kíyèsi i lọ́hùn ún ni!à ó, ìjọba Ọlọ́run ń bẹ nínú yín."

22 17.22: Mt 9.15; Mk 2.20; Lk 5.35. Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Ọjọ́ ń bọ̀, nígbà ̀yin yóò fẹ́ láti ̀kan nínú ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn, ̀yin yóò i. 23 17.23: Mt 24.23; Mk 13.21.Wọ́n fún yín , ó níhìn-ín!tàbí ó lọ́hùn ún!máa lọ, ṣe tẹ̀wọn. 24 17.24: Mt 24.27; If 1.7.Nítorí gẹ́gẹ́ mọ̀nàmọ́ti í kọ apá kan lábẹ́ ̀run, í mọ́lẹ̀ apá kejì lábẹ́ ̀run, bẹ́̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò ọjọ́ rẹ̀. 25 17.25: Lk 9.22.Ṣùgbọ́n ṣàìmá kọ́ jìyà ohun púpọ̀, a kọ̀ ́ lọ́dọ̀ ìran yìí.

26 17.26-27: Mt 24.37-39; Gẹ 6.5-8; 7.6-24. "ó ti ọjọ́ Noa, bẹ́̀ ni yóò ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn. 27 Wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń gbéyàwó, wọ́n ń fa ìyàwó fún ni, títí ó fi di ọjọ́ ti Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, kíkún omi , ó run gbogbo wọn.

28 17.28-30: Gẹ 18.20-33; 19.24-25. "ó ti ọjọ́ Lọti; wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń , wọ́n ń , wọ́n ń gbìn, wọ́n ń kọ́, 29 ṣùgbọ́n ọjọ́ náà Lọti jáde kúrò Sodomu, òjò iná àti sulfuru rọ̀ láti ̀run , ó run gbogbo wọn.

30 "Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni yóò ọjọ́ náà Ọmọ Ènìyàn yóò farahàn. 31 17.31: Mt 24.17-18; Mk 13.15-16; Lk 21.21.ọjọ́ náà, ẹni ó lórí ilé, ẹrù rẹ̀ ń bẹ ilẹ̀, ó ṣe sọ̀kalẹ̀ láti o; ẹni ó oko, ó ṣe padà sẹ́yìn. 32 17.32: Gẹ 19.26.rántí aya Lọti. 33 17.33: Mt 10.39; 16.25; Mk 8.35; Lk 9.24; Jh 12.25.Ẹnikẹ́ni ó ń àti gba ̀rẹ̀ yóò sọ ́ ; ẹnikẹ́ni ó sọ ́ yóò gbà á . 34 17.34-35: Mt 24.40-41.Mo fún yín, òru ọjọ́ náà, ènìyàn méjì yóò lórí àkéte kan; a ó ̀kan, a ó fi èkejì sílẹ̀. 35 Ènìyàn méjì yóò máa lọ ọlọ pọ̀; a ó ̀kan, a ó fi èkejì sílẹ̀."17.35 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí sílẹ̀. 36Àwọn ọkùnrin méjì yóò máa ṣiṣẹ́ nínú oko, a o mú ẹnìkan, a ó sì fi ẹni kejì sílẹ̀.

37 17.37: Mt 24.28. Wọ́n a lóhùn, wọ́n bi í , "Níbo, Olúwa?"

Ó fún wọn , "Níbi òkú gbé , níbẹ̀ pẹ̀ni igún ìkójọpọ̀ ."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-