Pular para o conteúdo
Publicidade

Luku 2

22 2.22-24: Le 12.2-8. Nígbà ọjọ́ ìwẹ̀Maria gẹ́gẹ́ òfin Mose, Josẹfu àti Maria gbé Jesu Jerusalẹmu láti fi í fún Olúwa 23 2.23: Ek 13.2,12.(a ti kọ ́ sínú òfin Olúwa , "Gbogbo ọmọ ọkùnrin ó ṣe àkọ́, òun ni a ó mímọ́ fún Olúwa"), 24 àti láti ẹbọ gẹ́gẹ́ èyí a nínú òfin Olúwa: "Àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì."

25 2.25: Lk 2.38; 23.51. kíyèsi i, ọkùnrin kan Jerusalẹmu, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Simeoni; ọkùnrin náà ṣe olóòtítọ́ àti olùfọkànsìn, ó ń retí ìtùnú Israẹli, ̀mímọ́ e. 26 A ti fihàn án láti ̀dọ̀ ̀Mímọ́ náà , òun yóò ikú, ó Kristi Olúwa. 27 Ó ti ipa ̀sínú tẹmpili. Nígbà àwọn òbí rẹ̀ gbé Jesu , láti ṣe fún un ìṣe òfin. 28 Nígbà náà ni Simeoni gbé e apá rẹ̀, ó fi ìbùkún fún Ọlọ́run, ó :

29 "Olúwa Olódùmarè, nígbà yìí ni ó jọ̀wọ́ ọmọ ̀dọ̀ rẹ lọ́wọ́ lọ,

àlàáfíà, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ.

30 2.30: Isa 52.10; Lk 3.6. Nítorí ojú mi ti ìgbàlà rẹ ,

31 ìwọ ti pèsè sílẹ̀ níwájú ènìyàn gbogbo;

32 2.32: Isa 42.6; 49.6; Ap 13.47; 26.23. ìmọ́lẹ̀ láti mọ́ àwọn aláìkọlà,

àti ògo Israẹli ènìyàn rẹ̀."

33 Ẹnu ya Josẹfu àti ìyá rẹ̀ nǹkan a ń sọ i wọ̀nyí. 34 Simeoni súre fún wọn, ó fún Maria ìyá rẹ̀ , "Kíyèsi i, a gbé ọmọ yìí kalẹ̀ fún ìṣubú àti ìdìde ̀pọ̀ ènìyàn Israẹli; àti fún àmì a ń sọ̀rọ̀-òdì ; 35 (idà yóò gún ìwọ náà ọkàn pẹ̀) á fi ìrònú ̀pọ̀ ọkàn hàn."

36 2.36: Ap 21.9; Jo 19.24; 1Tm 5.9. Ẹnìkan ń bẹ, Anna wòlíì, ọmọbìnrin Penueli, nínú ̀Aṣeri: ọjọ́ ogbó rẹ̀ pọ̀, ó ti ọkọ gbé ọdún méje láti ìgbà wúńdíá rẹ̀ ; 37 Ó ṣe opó títí ó fi di ẹni ọdún mẹ́rìnlélọ́gọ́rin, ẹni kúrò tẹmpili, ṣùgbọ́n ó ń fi àwẹ̀ àti àdúrà sin Ọlọ́run lọ́sàn án àti lóru. 38 Ó wólẹ̀ àkókò náà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run pẹ̀, ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún gbogbo àwọn ó ń retí ìdáǹdè Jerusalẹmu.

Veja também