Pular para o conteúdo
Publicidade

Luku 2

̀dọ́mọkùnrin Jesu ni tẹmpili

41 2.41: De 16.1-8; Ek 23.15. Àwọn òbí rẹ̀ a máa lọ Jerusalẹmu ọdọọdún àjọ ìrékọjá. 42 Nígbà ó di ọmọ ọdún méjìlá, wọ́n gòkè lọ Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ ìṣe àjọ náà. 43 Nígbà ọjọ́ wọn wọ́n ti ń padà bọ̀, ọmọ náà, Jesu dúró lẹ́yìn Jerusalẹmu; Josẹfu àti ìyá rẹ̀ mọ̀. 44 Ṣùgbọ́n wọ́n ṣe ó ̀gbẹ́ èrò, wọ́n rin ìrìn ọjọ́ kan; wọ́n a kiri nínú àwọn ará àti àwọn ojúlùmọ̀ wọn. 45 Nígbà wọn i, wọ́n padà Jerusalẹmu, wọ́n ń a kiri. 46 Ó ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta wọ́n i nínú tẹmpili ó jókòó àárín àwọn olùkọ́ni, ó ń gbọ́ tiwọn, ó ń bi wọ́n léèrè. 47 Ẹnu ya gbogbo àwọn ó gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀ fún òye àti ìdáhùn rẹ̀. 48 2.48: Mk 3.31-35.Nígbà wọ́n i, háà ṣe wọ́n, ìyá rẹ̀ bi í , "Ọmọ, èéṣe ìwọ fi ṣe bẹ́̀? ó, baba rẹ̀ àti èmi ti ń fi ìbànújẹ́ kiri."

49 Ó dáhùn fún wọn , "Èéṣe ̀yin fi ń mi kiri? ̀yin mọ̀ èmi ṣàìmá níbi iṣẹ́ Baba mi?" 50 ̀rọ̀ o sọ wọn.

51 2.51: Lk 2.19. Ó wọn sọ̀kalẹ̀ lọ Nasareti, fi ara balẹ̀ fún wọn, ṣùgbọ́n ìyá rẹ̀ pa gbogbo nǹkan wọ̀nyí mọ́ nínú ọkàn rẹ̀. 52 2.52: Lk 1.80; 2.40.Jesu ń pọ̀ ọgbọ́n, ń dàgbà, ó ojúrere ̀dọ̀ Ọlọ́run àti ènìyàn.

Veja também