Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 24

ojú ọnà Emmausi

13 kíyèsi i, àwọn méjì nínú wọn ń lọ ọjọ́ náà ìletò kan a ń Emmausi, ó jìnnà Jerusalẹmu níwọ̀n ọgọ́ta ibùsọ̀. 14 Wọ́n ń ara wọn sọ̀rọ̀ gbogbo nǹkan wọ̀nyí ó ṣẹlẹ̀. 15 Ó ṣe, wọ́n ti ń ara wọn sọ̀rọ̀, wọ́n ń ara wọn jíròrò, Jesu tìkára rẹ̀ súnmọ́ wọn, ó ń wọn rìn lọ. 16 24.16: Jh 20.14; 21.4.Ṣùgbọ́n a wọn lójú, wọn le mọ̀ ́n.

17 Ó bi wọ́n , "̀rọ̀ kín ni ̀yin ń ara yín sọ, ̀yin ti ń rìn?"

Wọ́n dúró jẹ́, wọ́n fajúro. 18 ̀kan nínú wọn, a ń Kileopa, dáhùn fún un , "Àlejò à ni ìwọ Jerusalẹmu, ìwọ mọ ohun ó ṣẹ̀ níbẹ̀ ọjọ́ wọ̀nyí?"

19 24.19: Mt 21.11; Lk 7.16; 13.33; Ap 3.22. Ó bi wọ́n , "Kín ni?"

Wọ́n fún un , "ti Jesu ti Nasareti, ẹni ó jẹ́ wòlíì, ó pọ̀ ìṣe àti ọrọ̀ níwájú Ọlọ́run àti gbogbo ènìyàn, 20 àti àwọn olórí àlùfáà àti àwọn alàgbà wa ti fi òun wọn lọ́wọ́ láti a lẹ́bi ikú, àti wọ́n ti kàn án mọ́ àgbélébùú. 21 Bẹ́̀ ni òun ni àwa ti ìrètí , òun ni ìbá Israẹli ìdè. Àti pẹ̀gbogbo nǹkan wọ̀nyí, òní ni ó di ọjọ́ kẹta nǹkan wọ̀nyí ti ṣẹlẹ̀. 22 Àwọn obìnrin kan pẹ̀nínú ẹgbẹ́ wa, wọ́n lọ si ibojì kùtùkùtù, lẹ́nu, 23 nígbà wọn òkú rẹ̀, wọ́n , àwọn ìran àwọn angẹli wọ́n , ó láààyè. 24 24.24: Jh 20.3-10.Àti àwọn kan wọ́n pẹ̀wa lọ ibojì, wọ́n i gẹ́gẹ́ àwọn obìnrin náà ti , ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ni wọn ."

25 Ó fún wọn , "̀yin òye , yigbì àyà láti gba gbogbo èyí àwọn wòlíì ti gbọ́, 26 ha yẹ Kristi ó jìyà nǹkan wọ̀nyí ó wọ inú ògo rẹ̀ lọ." 27 24.27: Lk 24.44-45; Ap 28.23; 1Pt 1.11.Ó bẹ̀rẹ̀ láti Mose àti gbogbo àwọn wòlíì , ó túmọ̀ nǹkan fún wọn nínú ìwé mímọ́ gbogbo nípa ti ara rẹ̀.

28 24.28: Mk 6.48. Wọ́n súnmọ́ ìletò wọ́n ń lọ, ó ṣe ẹni yóò lọ iwájú. 29 Wọ́n rọ̀ ́, , "wa dúró: nítorí ó di ọjọ́ alẹ́, ọjọ́ kọjá tán." Ó wọlé lọ, ó wọn dúró.

30 24.30: Lk 9.16; 22.19. Ó ṣe, ó ti wọn jókòó ti oúnjẹ, ó àkàrà, ó súre i, ó ú, ó fi fún wọn. 31 Ojú wọn , wọ́n mọ̀ ́n, ó mọ́ wọn ojú. 32 Wọ́n ara wọn sọ , "Ọkàn wa ha gbiná nínú wa, nígbà ó ń wa sọ̀rọ̀ ó ń túmọ̀ ìwé mímọ́ fún wa!"

33 Wọ́n dìde wákàtí kan náà, wọ́n padà lọ Jerusalẹmu, wọ́n àwọn mọ́kànlá péjọ, àti àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ wọn. 34 24.34: 1Kọ 15.5.Wọn si , "Olúwa jíǹde nítòótọ́, ó ti fi ara hàn fún Simoni!" 35 Àwọn náà ròyìn nǹkan ó ṣe ̀, àti ó ti di mọ̀ fún wọn bíbu àkàrà.

Veja também