Publicidade

Lucas 4

Ìdánwò Jesu

1 4.1-13: Mt 4.1-11; Mk 1.12-13. Jesu kún fún ̀Mímọ́, ó padà ti Jordani , a ti ọwọ́ ̀darí rẹ̀ ijù, 2 4.2: De 9.9; 1Ọb 19.8.Ogójì ọjọ́ ni a fi dán an lọ́wọ́ èṣù. jẹ ohunkóhun ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì: nígbà wọ́n parí, lẹ́yìn náà ni ebi ń pa á.

3 Èṣù fún un , "ìwọ ṣe Ọmọ Ọlọ́run, pàṣẹ fún òkúta yìí ó di àkàrà."

4 4.4: De 8.3. Jesu dáhùn, ó fún un , "A ti kọ̀rẹ̀ , Ènìyàn yóò láààyè nípa àkàrà nìkan.’ "

5 Lójúkan náà, èṣù un lọ orí òkè gíga, ó fi gbogbo ilẹ̀ ọba ayé hàn án. 6 4.6: 1Jh 5.19.Èṣù fún un , "Ìwọ ni èmi ó fi gbogbo agbára yìí àti ògo wọn fún: nítorí á ti fi fún mi. Ẹnikẹ́ni ó , èmi a fi í fún. 7 Ǹjẹ́ ìwọ foríbalẹ̀ fún mi, gbogbo rẹ̀ ni yóò jẹ́ tìrẹ."

8 4.8: De 6.13. Jesu dáhùn ó fún un , "Kúrò lẹ́yìn mi, Satani, nítorí a kọ̀rẹ̀ , Ìwọ foríbalẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, òun nìkan ṣoṣo ni ìwọ ó máa sìn.’ "

9 Èṣù un lọ Jerusalẹmu, ó gbé e ibi ṣóńṣó tẹmpili, ó fún un , "ìwọ ṣe Ọmọ Ọlọ́run, bẹ́ sílẹ̀ fún ara rẹ láti ibí yìí. 10 4.10-11: Sm 91.11-12.A ti kọ̀rẹ̀ ,

" Yóò pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí rẹ,

láti máa ṣe ìtọ́rẹ;

11 àti ọwọ́ wọn ni wọn ó gbé sókè,

ìwọ ó ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gbún òkúta.’ "

12 4.12: De 6.16. Jesu dáhùn ó fún un , "A ti kọ́ , Ìwọ gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run rẹ .’ "

13 4.13: Lk 22.28. Nígbà èṣù parí ìdánwò náà gbogbo, ó fi í sílẹ̀ lọ fun à kan.

A kọ Jesu ni Nasareti

14 4.14: Mt 4.12; Mk 1.14; Mt 9.26; Lk 4.37. Jesu fi agbára ̀padà Galili, òkìkí rẹ̀ kàn kálẹ̀ gbogbo agbègbè ó i . 15 4.15: Mt 4.23; 9.35; 11.1.Ó ń kọ́ni nínú Sinagọgu wọn; a ń yìn ín lógo láti ̀dọ̀ gbogbo àwọn ènìyàn .

16 4.16-30: Mt 13.53-58; Mk 6.1-6; Isa 13.14-16. Ó Nasareti, níbi a gbé ti tọ́ dàgbà: ìṣe rẹ̀ ti , ó wọ inú Sinagọgu lọ ọjọ́ ìsinmi, ó dìde láti kàwé. 17 A fi ìwé wòlíì Isaiah fún un. Nígbà ó ṣí ìwé náà, ó ibi a gbé kọ ́ :

18 "̀Olúwa ń bẹ lára mi,

nítorí ó fi àmì òróró yàn

láti wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì.

Ó ti rán mi láti wàásù ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn, àti

ìmúnríran fún àwọn afọ́,

àti láti jọ̀wọ́ àwọn a pa lára lọ́wọ́,

19 láti kéde ọdún ojúrere Olúwa."

20 Ó pa ìwé náà , ó fi í fún ìránṣẹ́, ó jókòó. Gbogbo àwọn ó ń bẹ nínú Sinagọgu tẹjúmọ́ ọn. 21 Ó bẹ̀rẹ̀ í fún wọn , "Lónìí ìwé mímọ́ yìí ṣẹ etí yín."

22 4.22: Jh 6.42; 7.15. Gbogbo wọn jẹ́rìí rẹ̀, háà ṣe wọ́n ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ ń jáde ẹnu rẹ̀, wọ́n , "Ọmọ Josẹfu kọ́ yìí?"

23 4.23: Mk 1.21; 2.1; Jh 4.46. Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ ni ̀yin ó pa òwe yìí mi , Oníṣègùn, wo ara rẹ̀ sàn! Àwọn ohun àwa gbọ́ o ti ọwọ́ rẹ ṣe Kapernaumu, ṣe é níhìn-ín yìí pẹ̀ilẹ̀ ara rẹ.’ "

24 4.24: Jh 4.44. Ó , "Lóòótọ́ ni mo fún un yín, wòlíì a tẹ́wọ́gbà ilẹ̀ baba rẹ̀. 25 4.25: 1Ọb 17.1,8-16; 18.1; Jk 5.17-18.Ṣùgbọ́n mo fún un yín nítòótọ́, opó púpọ̀ ni ó Israẹli nígbà ọjọ́ wòlíì Elijah, nígbà ̀run fi ọdún mẹ́ta òun oṣù mẹ́, nígbà ìyàn ńlá fi ilẹ̀ gbogbo. 26 ẹnìkan nínú wọn a rán Elijah , ṣe obìnrin opó kan Sarefati, ìlú kan Sidoni. 27 4.27: 2Ọb 5.1-14.Adẹ́tẹ̀ púpọ̀ ń bẹ Israẹli nígbà wòlíì Eliṣa; ṣí ̀kan nínú wọn a wẹ̀nùmọ́, ṣe Naamani ará Siria."

28 Nígbà gbogbo àwọn ó nínú Sinagọgu gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, inú bi wọ́n gidigidi, 29 4.29: Ap 7.58; Nu 15.35.wọ́n dìde, wọ́n í sóde ̀yìn ìlú, wọ́n á lọ bèbè òkè níbi wọ́n gbé tẹ ìlú wọn , wọn à sọ sílẹ̀ ògèdèǹgbé. 30 4.30: Jh 8.59; 10.39.Ṣùgbọ́n ó kọjá láàrín wọn, ó tirẹ̀ lọ.

Jesu ̀èṣù jáde

31 4.31-37: Mk 1.21-28. Ó sọ̀kalẹ̀ Kapernaumu, ìlú kan Galili, ó ń kọ́ wọn ọjọ́ ìsinmi. 32 4.32: Mt 7.28; 13.54; 22.33; Mk 11.18; Jh 7.46.Ẹnu wọ́n ̀kọ́ rẹ̀: nítorí tàṣẹtàṣẹ ni ̀rọ̀ rẹ̀.

33 Ọkùnrin kan nínú Sinagọgu, ẹni ó ̀àìmọ́, ó kígbe ohùn rara, 34 "Ó , kín ni ṣe tàwa tìrẹ, Jesu ará Nasareti? Ìwọ́ láti pa run ? Èmí mọ ẹni ìwọ í ṣe, Ẹni Mímọ́ Ọlọ́run."

35 Jesu a gidigidi, ó fun pe, "Pa ẹnu rẹ mọ́, o jáde lára rẹ̀." Nígbà ̀èṣù náà gbé e ṣánlẹ̀ àwùjọ, ó jáde kúrò lára rẹ̀, pa á lára.

36 Ẹnu ya gbogbo wọn, wọ́n ń ara wọn sọ , "Irú ̀kọ́ kín ni èyí? Nítorí pẹ̀àṣẹ àti agbára ni ó fi àwọn ̀àìmọ́ , wọ́n jáde kúrò." 37 4.37: Lk 4.14; 5.15; Mt 9.26.Òkìkí rẹ̀ kàn níbi gbogbo agbègbè ilẹ̀ náà yíká.

Jesu wo ̀pọ̀ ènìyàn sàn

38 4.38-41: Mt 8.14-17; Mk 1.29-34. Nígbà ó dìde kúrò nínú Sinagọgu, ó wọ̀ ilé Simoni lọ; ibà ti ìyá ìyàwó Simoni dùbúlẹ̀, wọ́n bẹ̀ ́ nítorí rẹ̀. 39 Ó súnmọ́ , ó ibà náà ; ibà náà fi sílẹ̀. O dìde lọ́gán, ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.

40 Nígbà oòrùn ń wọ̀, àwọn ènìyàn gbe àwọn aláìsàn, onírúurú àìsàn sọ́dọ̀ Jesu; ó fi ọwọ́ olúkúlùkù wọn, ó wọn láradá. 41 Àwọn ̀èṣù jáde lára ẹni púpọ̀ pẹ̀, wọ́n ń kígbe, , "Ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run!" Ó ń wọn jẹ́ wọn ó fọhùn, nítorí wọ́n mọ̀ Òun ni Kristi náà.

42 4.42-43: Mk 1.35-38. Nígbà ilẹ̀ mọ́, Jesu jáde lọ, ó ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀. Ìjọ ènìyàn ń a kiri, wọ́n tọ̀ ́ , wọ́n a dúró, nítorí ó ba à lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn. 43 Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "Èmi ṣàìmá wàásù ìyìnrere ti ìjọba Ọlọ́run fún àwọn ìlú mìíràn pẹ̀, nítorí náà ni a ṣe rán mi." 44 4.44: Mt 4.23; Mk 1.39; Mt 9.35.Ó ń wàásù nínú Sinagọgu ti Judea.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-