Publicidade

Marcos 6

Wòlíì ọlá

1 Jesu fi ibẹ̀ sílẹ̀ lọ ìlú rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 2 Nígbà ó di ọjọ́ ìsinmi, ó lọ Sinagọgu láti kọ́ àwọn ènìyàn, ẹnu ya àwọn ènìyàn púpọ̀ ó gbọ́.

Wọ́n , "Níbo ni ọkùnrin yìí gbé ti nǹkan wọ̀nyí? Irú ọgbọ́n ni èyí a fi fún un, irú iṣẹ́ ìyanu báyìí ń ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe? 3 Gbẹ́nàgbẹ́náà kọ́ yìí? Ọmọ Maria àti arákùnrin Jakọbu àti Josẹfu, Judasi àti Simoni? Àwọn arábìnrin rẹ̀ gbogbo ha kọ́ ni ó ń wa gbé níhìn-ín yìí?" Wọ́n kọsẹ̀ lára rẹ̀.

4 Nígbà náà, Jesu fún wọn , "A máa ń bu ọlá fún wòlíì níbi gbogbo àfi ìlú ara rẹ̀ àti láàrín àwọn ìdílé àti àwọn ẹbí òun pàápàá." 5 Nítorí àìgbàgbọ́ wọn, òun ṣe iṣẹ́ ìyanu ńlá láàrín wọn, àfi àwọn aláìsàn díẹ̀ ó gbé ọwọ́ lórí, wọ́n ìwòsàn.

Jesu rán ọmọ-ẹ̀yìn méjìlá jáde

6 Ẹnu si á nítorí àìgbàgbọ́ wọn. Lẹ́yìn náà, Jesu lọ àárín àwọn ìletò kéékèèké, ó ń kọ́ wọn. 7 Ó pe àwọn méjìlá náà sọ́dọ̀ rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ rán wọn lọ méjì méjì, Ó fi àṣẹ fún wọn lórí ̀àìmọ́.

8 O sọ fún wọn , wọn gbọdọ̀ ohunkóhun lọ́wọ́, àfi ̀ìtìlẹ̀ wọn. Wọn gbọdọ̀ oúnjẹ, àpò ìgbànú, tàbí owó lọ́wọ́. 9 Wọn tilẹ̀ gbọdọ̀ ìpààrọ̀ bàtà tàbí aṣọ lọ́wọ́. 10 Jesu , "dúró ilé kan ìletò kan. ṣe sípò padà láti ilé ilé, nígbà ìlú náà. 11 Ẹnikẹ́ni gbà yín, gbọ́rọ̀ yín, nígbà ̀yin jáde kúrò níbẹ̀, gbọn eruku ẹsẹ̀ yín síbẹ̀ fún ̀fún wọn."

12 Wọ́n jáde lọ láti wàásù ìrònúpìwàdà fún àwọn ènìyàn. 13 Wọ́n ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ̀àìmọ́ jáde. Wọ́n ń fi òróró kun orí àwọn ara wọn , wọ́n wọn láradá.

A bẹ́ Johanu onítẹ̀bọmi lórí

14 Láìpẹ́, ọba Herodu gbọ́ nípa Jesu, nítorí níbi gbogbo ni a ti ń sọ̀rọ̀ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀. Ọba náà , "Johanu Onítẹ̀bọmi jíǹde kúrò nínú òkú, nítorí náà ni iṣẹ́ ìyanu ṣe ń ṣe láti ọwọ́ rẹ."

15 Àwọn mìíràn , "Elijah ."

Àwọn mìíràn , "Wòlíì ̀kan lára àwọn àtijọ́ ti tún padà sáyé."

16 Ṣùgbọ́n nígbà Herodu gbọ́ èyí, ó "Johanu mo bẹ́ lórí ni ó ti jíǹde kúrò nínú òkú."

17 Herodu fúnra rẹ̀ ti ránṣẹ́ Johanu, tìkára rẹ̀ sínú túbú nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀ nítorí ó fi ṣe aya. 18 Johanu ti fún Herodu , "tọ́ láti fi ìyàwó arákùnrin rẹ ṣe aya." 19 Nítorí náà ni Herodia ṣe sínú, òun fẹ́ pa á, ṣùgbọ́n le ṣe é. 20 Nítorí Herodu bẹ̀Johanu, ó mọ̀ ́n ni olóòtítọ́ ènìyàn àti ẹni mímọ́, ó ń tọ́rẹ̀. Nígbà Herodu ba gbọ́rọ̀ Johanu, ó máa ń dààmú síbẹ̀, ó fi ayọ̀ gbọ́rọ̀ rẹ̀.

21 Níkẹyìn Herodia ààyè. Àkókò yìí ni ọjọ́ ìbí Herodu, òun pèsè àsè ààfin ọba fún àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀: àwọn balógun àti àwọn ènìyàn pàtàkì Galili. 22 Nígbà náà, ni ọmọbìnrin Herodia wọlé láti . Inú Herodu àti àwọn àlejò rẹ̀ dùn bẹ́̀.

Ọba sọ fún ọmọbìnrin náà , "Béèrè ohunkóhun ìwọ fẹ́ lọ́wọ́ mi, èmi ó fi fún ." 23 Ó búra fún un , "Ohunkóhun ìwọ fẹ́, ìbá à ṣe ìdajì ìjọba mi ni, èmi yóò fi fún ."

24 Ó jáde lọ sọ fún ìyá rẹ̀ , "ń béèrè?"

Ó dáhùn , "Orí Johanu Onítẹ̀bọmi."

25 Ọmọbìnrin yìí sáré padà sọ́dọ̀ Herodu ọba. Ó fún un , "Mo ń fẹ́ orí Johanu Onítẹ̀bọmi nísinsin yìí nínú àwopọ̀kọ́."

26 Inú ọba bàjẹ́ gidigidi, ṣùgbọ́n nítorí àwọn ìbúra rẹ, àti nítorí àwọn ó a jókòó pọ̀, fẹ́ kọ̀ fún un. 27 Nítorí èyí, ọba rán ̀ṣọ́ kan, ó fi àṣẹ fún un , ó gbé orí Johanu . Ọkùnrin náà lọ, ó bẹ́ Johanu lórí nínú túbú. 28 Ó gbé orí Johanu wa nínú àwopọ̀kọ́. Ó gbé e fún ọmọbìnrin náà. Òun gbé e tọ ìyá rẹ̀ lọ. 29 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu gbọ́, wọ́n gbé òkú rẹ̀, wọ́n lọ tẹ́ sínú ibojì.

Jesu bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn

30 Àwọn aposteli ara wọn jọ ̀dọ̀ Jesu, wọ́n ròyìn ohun gbogbo wọ́n ti ṣe àti ohun gbogbo wọ́n ti kọ́ni. 31 Nígbà Jesu i ̀pọ̀ ènìyàn ń lọ wọ́n ń bọ̀ bẹ́̀ ààyè fún wọn láti jẹun, ó fún wọn , "jẹ́ a kúrò láàrín ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí fún ìgbà díẹ̀, a sinmi."

32 Nítorí náà, wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi kúrò níbẹ̀ lọ ibi ó parọ́rọ́. 33 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ ènìyàn ni o wọn nígbà wọ́n ń lọ. Àwọn wọ̀nyí tún láti ìlú ńlá gbogbo wọn sáré gba etí Òkun, wọ́n ṣáájú wọn gúnlẹ̀ èbúté. 34 Jesu ti ń sọ̀kalẹ̀ láti inú ọkọ̀ náà, ó ̀pọ̀ ènìyàn i àtẹ̀yìnwá, wọ́n ti ń dúró e. Ó káàánú fún wọn, nítorí wọ́n dàbí àgùntàn olùtọ́. Ó kọ́ wọn ni ̀pọ̀ nǹkan ó yẹ wọ́n mọ̀.

35 Nígbà ọjọ́ ti lọ tán, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọ́n fún un , ibi aṣálẹ̀ ni ìbí yìí, ọjọ́ lọ tán. 36 "Rán àwọn ènìyàn wọ̀nyí láti lọ àwọn abúlé àti ìlú láti ra oúnjẹ fún ara wọn."

37 Ṣùgbọ́n Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "fún wọn oúnjẹ."

Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn fún , "Èyí yóò wa owó iṣẹ́ ̀oṣù mẹ́jọ, ṣe a lọ fi èyí ra àkàrà fún àwọn ̀pọ̀ ènìyàn yìí láti jẹ."

38 Jesu tún béèrè , "Ìṣù àkàrà mélòó ni ̀yin ni lọ́wọ́? lọ ó."

Wọ́n padà jíṣẹ́ , "Ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì."

39 Nígbà náà ni Jesu sọ fún ̀pọ̀ ènìyàn náà a wọn jókòó lẹ́gbẹ̀̀gbẹ́ lórí koríko. 40 Lẹ́sẹ̀kan náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ í jókòó, àádọ́ta tàbí ọgọọgọ́rùn-ún. 41 Nígbà ó ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì náà, ó gbé ojú rẹ̀ sókè ̀run. Ó dúpẹ́ fún oúnjẹ náà, ó wọ́n wẹ́wẹ́, ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti gbé e kalẹ̀ síwájú àwọn ènìyàn náà àti àwọn ẹja méjì náà ni ó pín fún gbogbo wọn. 42 Gbogbo wọn jẹ àjẹyó. 43 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn agbọ̀n méjìlá ó kún fún àjẹkù àkàrà àti ti ẹja pẹ̀. 44 Àwọn ó jẹ́ àkàrà náà ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ọkùnrin.

Jesu rìn lórí omi

45 Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ lẹ́yìn èyí, Jesu pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti padà sínú ọkọ̀ wọn ṣáájú rékọjá Betisaida. Níbẹ̀ ni òun yóò ti pẹ̀wọn láìpẹ́. Nítorí òun fúnra a rẹ̀ yóò dúró sẹ́yìn láti i àwọn ènìyàn túká lọ ilé wọn. 46 Lẹ́yìn náà, ó lọ sórí òkè láti lọ gbàdúrà.

47 Nígbà ó di alẹ́, ọkọ̀ láàrín Òkun, òun nìkan lórí ilẹ̀. 48 Ó i àwọn ọmọ-ẹ̀yìn nínú wàhálà púpọ̀ wíwa ọkọ̀ náà nítorí ti ìjì líle ṣe ọwọ́ òdì wọn, nígbà ó ìwọ̀n ìṣọ́ kẹrin òru, ó tọ̀ wọ́n , ó ń rìn lórí omi Òkun, òun fẹ́ wọn kọjá, 49 ṣùgbọ́n nígbà wọ́n i ó ń rìn, wọ́n iwin ni. Wọ́n kígbe sókè lóhùn rara, 50 nítorí gbogbo wọn ni ó i, ̀wọ́n.

Ṣùgbọ́n òun sọ̀rọ̀ wọn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ , "ọkàn le! Èmi ni. bẹ̀." 51 Nígbà náà ni ó gòkè sínú ọkọ̀ pẹ̀wọn, ìjì líle náà dáwọ́ dúró. ̀wọ́n rékọjá gidigidi, ẹnu wọ́n. 52 Wọn ni òye iṣẹ́ ìyanu ti ìṣù àkàrà, nítorí ti ọkàn wọn yigbì.

53 Lẹ́yìn wọ́n la Òkun náà kọjá, wọ́n gúnlẹ̀ Genesareti. Wọ́n so ọkọ̀ èbúté. 54 Wọ́n jáde kúrò nínú ọkọ̀. Àwọn ènìyàn níbẹ̀ Jesu, wọ́n a mọ̀ ́n. 55 Wéré, wọ́n ròyìn dídé rẹ̀, gbogbo àwọn ènìyàn sáré gbé gbogbo àwọn aláìsàn lórí àkéte wọn pàdé rẹ̀. 56 ibi gbogbo ó , yálà abúlé, ìlú ńlá tàbí àrọ́ko, ń ṣe ni wọ́n ń àwọn aláìsàn pàdé rẹ̀ àárín ọjà. Wọ́n ń bẹ̀ ́ ó jẹ́ wọn fi ọwọ́ kan etí aṣọ rẹ̀, gbogbo àwọn wọ́n fi ọwọ́ kàn án ni a láradá.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-