Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 7

Ìgbàgbọ́ obìnrin ará Kenaani

24 7.24-30: Mt 15.21-28. Nígbà náà ni Jesu kúrò Galili, ó lọ agbègbè Tire àti Sidoni, ó gbìyànjú láti nìkan pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún àkókò díẹ̀, ṣùgbọ́n eléyìí ṣe é ṣe, nítorí pẹ́ púpọ̀ ó wọ ìlú nígbà ìròyìn dídé rẹ̀ tàn káàkiri. 25 Láìpẹ́, obìnrin kan ọmọbìnrin rẹ̀ ̀àìmọ́ tọ̀ ́ , ó ti gbọ́ nípa Jesu, ó , ó wólẹ̀ lẹ́sẹ̀ Jesu. 26 Giriki obìnrin náà, Siro-Fonisia orílẹ̀-èdè rẹ̀. Ó bẹ Jesu ó òun ̀èṣù náà jáde lára ọmọbìnrin òun.

27 Jesu sọ fún obìnrin yìí , "àkọ́kọ́, ó yẹ a fi oúnjẹ tẹ́ àwọn ọmọ lọ́rùn . Nítorí tọ́ a oúnjẹ àwọn ọmọ fún àwọn ajá."

28 Obìnrin náà dáhùn , "Òótọ́ ni ̀rọ̀ yín Olúwa, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ajá pàápàá a máa àǹfààní láti jẹ èérún oúnjẹ ó bọ́ sílẹ̀ láti orí tábìlì."

29 "Ó fún un , nítorí ̀rọ̀ yìí, máa lọ, ̀àìmọ́ náà ti jáde kúrò lára ọmọbìnrin rẹ."

30 Nígbà ó padà ilé, ó ọmọbìnrin rẹ̀ ìdùbúlẹ̀ jẹ́jẹ́ lórí ibùsùn, ̀àìmọ́ náà ti fi í sílẹ̀.

Veja também