Publicidade

Mateus 11

Jesu àti Johanu onítẹ̀bọmi

1 Lẹ́yìn ìgbà Jesu ti parí ̀rọ̀ ó ń sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá, ó ti ibẹ̀ rékọjá láti máa kọ́ni àti láti máa wàásù àwọn ìlú Galili gbogbo.

2 Nígbà Johanu gbọ́ ohun Kristi ṣe nínú ̀wọ̀n, ó rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ 3 láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ṣe ìwọ ni ẹni ń bọ̀ tàbí a máa retí ẹlòmíràn?"

4 Jesu dáhùn ó , "padà lọ, sọ fún Johanu ohun ̀yin gbọ́, àti èyí ̀yin . 5 Àwọn afọ́ń ríran, àwọn amúnkùn ún rìn, a ń wẹ àwọn adẹ́tẹ̀ mọ́ kúrò nínú ̀tẹ̀ wọn, àwọn adití ń gbọ́rọ̀, a ń àwọn òkú dìde, a ń wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì. 6 Alábùkún fún ni ẹni ohun ìkọ̀sẹ̀ nípa mi."

7 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ti lọ tán, Jesu bẹ̀rẹ̀ í sọ fún ̀pọ̀ ènìyàn nípa ti Johanu: "ni ̀yin jáde lọ aginjù? Ewéko afẹ́fẹ́ ń mi? 8 ṣe bẹ́̀, ni ̀yin lọ òde lọ í ? Ọkùnrin a wọ̀ ni aṣọ dáradára? Rárá àwọn ti ó wọ aṣọ dáradára ààfin ọba. 9 Àní jáde láti lọ ? Wòlíì? Bẹ́̀ ni, mo fún yín, ó ju wòlíì lọ." 10 Èyí ni ẹni a ti kọ̀rẹ̀ :

" Èmi yóò rán ìránṣẹ́ mi síwájú rẹ,

ẹni yóò tún ̀rẹ ṣe níwájú rẹ.

11 Lóòótọ́ ni fún yín, nínú àwọn a nínú obìnrin, ẹni ó í dìde ó ga ju Johanu onítẹ̀bọmi lọ, síbẹ̀ ẹni ó kéré ìjọba ̀run ni ó pọ̀ú lọ. 12 Láti ìgbà ọjọ́ Johanu onítẹ̀bọmi títí di àkókò yìí ni ìjọba ̀run ti di à fi agbára wọ̀, àwọn alágbára ń fi ipá gbà á. 13 Nítorí náà gbogbo òfin àti wòlíì ni ó sọtẹ́lẹ̀ Johanu ó . 14 ̀yin yóò gbà á, èyí ni Elijah ń bọ̀ . 15 Ẹni ó etí, ó gbọ́.

16 "ni èmi ìbá fi ìran yìí ? Ó dàbí àwọn ọmọ kékeré ń jókòó ọjà wọ́n ń pe àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn:

17 " Àwa ń fun fèrè fún yín,

̀yin ;

àwa kọrin ̀fọ̀

̀yin káàánú.

18 Nítorí Johanu a yín jẹ bẹ́̀ ni mu, ̀yin , Ó ̀èṣù. 19 Ọmọ Ènìyàn a yín jẹun, ó yin mu, wọ́n , ̀jẹun àti ̀mùtí; ̀rẹ́ àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.’ Ṣùgbọ́n a ọgbọ́n láre nípa ìṣe rẹ̀."

Ègbé ni fún àwọn ìlú ronúpìwàdà

20 Nígbà náà ni Jesu bẹ̀rẹ̀ í ìlú ó ti ṣe ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ , nítorí wọn ronúpìwàdà. 21 Ó , "Ègbé ni fún ìwọ Korasini, ègbé ni fún ìwọ Betisaida! Ìbá ṣe a ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu a ṣe nínú yín a ṣe ni Tire àti Sidoni, àwọn ènìyàn wọn ìbá ti ronúpìwàdà ti pẹ́ nínú aṣọ ̀fọ̀ àti eérú. 22 Ṣùgbọ́n mo fún yín, yóò sàn fún Tire àti Sidoni ọjọ́ ìdájọ́ fún yín. 23 Àti ìwọ Kapernaumu, a ó ha gbé ga sókè ̀run? Rárá, a ó rẹ̀ ́ sílẹ̀ ipò òkú. Nítorí, ìbá ṣe a ti ṣe iṣẹ́ ìyanu a ṣe nínú rẹ Sodomu, òun ìbá títí di òní. 24 Lóòótọ́ yóò sàn fún ilẹ̀ Sodomu ọjọ́ ìdájọ́ fún ìwọ lọ."

Ìsinmi fún aláàárẹ̀

25 Nígbà náà ni Jesu , "Mo yìn Baba, Olúwa ̀run àti ayé, nítorí ìwọ ti fi òtítọ́ yìí pamọ́ fún àwọn jẹ́ ọlọ́gbọ́n àti amòye, Ìwọ ti fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́. 26 Bẹ́̀ ni, Baba, nítorí ó ́ láti ṣe bẹ́̀.

27 "Ohun gbogbo ni Baba mi ti fi ìkáwọ́ mi. ẹni ó mọ ọmọ ṣe Baba, bẹ́̀ ni ẹnikẹ́ni ó mọ Baba, ṣe ọmọ, àti àwọn ọmọ yan láti fi ara hàn fún.

28 "sọ́dọ̀ mi gbogbo ̀yin ń ṣiṣẹ́ a di ẹrù wíwúwo lórí, èmi yóò fún yín ìsinmi. 29 gbé àjàgà mi wọ̀. kọ́ ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi nítorí onínútútù àti onírẹ̀lẹ̀ ọkàn ni èmi, ̀yin yóò ri ìsinmi fún ọkàn yín. 30 Nítorí àjàgà mi rọrùn ẹrù mi fúyẹ́."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-