Publicidade

Mateus 18

Ẹni ó tóbi ìjọba ̀run

1 àkókò náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu tọ̀ ́ , wọ́n bi í léèrè , "Ta ni ẹni ti ó pọ̀ìjọba ̀run?"

2 Jesu pe ọmọ kékeré kan ̀dọ̀ ara rẹ̀. Ó un dúró láàrín wọn. 3 Ó , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, àfi ̀yin padà dàbí àwọn ọmọdé, ̀yin yóò wọ ìjọba ̀run. 4 Nítorí náà, ẹni ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ ọmọdé yìí, ni yóò pọ̀ jùlọ ìjọba ̀run. 5 Àti , ẹnikẹ́ni ó gba ọmọ kékeré èyí nítorí orúkọ mi, gbà .

6 "Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni nínú yín ó ̀kan nínú àwọn ọmọ kékeré wọ̀nyí ó gbà gbọ́ ṣìnà, yóò sàn fún un a so òkúta ńlá mọ́ ọn ọrùn, a í ìsàlẹ̀ ibú omi Òkun. 7 Ègbé ni fún ayé nítorí gbogbo ohun ìkọ̀sẹ̀ rẹ̀! Ohun ìkọ̀sẹ̀ le ṣe , ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin náà nípasẹ̀ ẹni ìkọ̀sẹ̀ náà ti ! 8 Nítorí náà, ọwọ́ tàbí ẹsẹ̀ rẹ yóò dẹ́ṣẹ̀, e kúrò, o ú . Ó kúkú sàn fún láti wọ ìjọba ̀run akéwọ́ tàbí akésẹ̀ ju o ni ọwọ́ méjì àti ẹsẹ̀ méjì ki a sọ ́ sínú iná ayérayé. 9 ojú rẹ yóò o dẹ́ṣẹ̀, yọ ́ kúrò ó sọ ́ . Ó kúkú sàn fún láti lọ sínú ìyè pẹ̀ojú kan, ju o ojú méjì, a ́ iná ̀run àpáàdì.

Òwe àgùntàn sọnù

10 "i fi ojú tẹ́ńbẹ́̀kan nínú àwọn kéékèèké wọ̀nyí. Lóòótọ́ ni mo fún yin , nígbà gbogbo ni ̀run ni àwọn angẹli ń wo ojú Baba mi ń bẹ ̀run.

12 "ni ̀yin ? ọkùnrin kan ni ọgọ́rùn-ún àgùntàn, ẹyọ kan nínú wọn sọnù, ṣé òun yóò fi mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún ìyókù sílẹ̀ sórí òkè láti lọ ẹyọ kan náà ? 13 Ǹjẹ́ òun á i, lóòótọ́ ni mo fún yín, ǹjẹ́ ̀yin mọ̀ inú rẹ̀ yóò dùn nítorí rẹ̀ ju àwọn mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún lọ? 14 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, ni í ṣe ìfẹ́ Baba yín ń bẹ ̀run, ̀kan nínú àwọn kékeré wọ̀nyí ó ṣègbé.

Arákùnrin ó ṣẹ̀

15 "arákùnrin rẹ ṣẹ̀ ́, lọ ìkọ̀kọ̀ o sọ ̀bi rẹ̀ fún un. ó gbọ́ tìrẹ, ìwọ ti arákùnrin kan bọ̀ ipò. 16 Ṣùgbọ́n òun tẹ́, nígbà náà ẹnìkan tàbí ẹni méjì pẹ̀rẹ, tún padà ̀dọ̀ rẹ̀ lẹ́̀kan i, ̀rọ̀ náà le fi ìdí múlẹ̀ pẹ̀àwọn ẹlẹ́rìí méjì tàbí mẹ́ta náà. 17 òun tún kọ̀ láti tẹ́wọn, nígbà náà sọ fún ìjọ ènìyàn Ọlọ́run. o kọ̀ láti gbọ́ ti ìjọ ènìyàn Ọlọ́run, jẹ́ ó dàbí kèfèrí tàbí agbowó òde.

18 "Lóòótọ́ ni mo fún yín, ohunkóhun ̀yin ayé, ni a ̀run. Ohunkóhun ti ̀yin ti ni ayé, á ò u ̀run.

19 "Mo tún sọ èyí fún yín, ̀yin méjì fi ohùn ṣọ̀kan ayé yìí, nípa ohunkóhun béèrè, Baba mi ti ń bẹ ̀run yóò ṣe é fún yín. 20 Nítorí níbi ti ènìyàn méjì tàbí mẹ́ta ara jọ ni orúkọ mi, èmi yóò láàrín wọn níbẹ̀."

Òwe aláìláàánú ọmọ ̀dọ̀

21 Nígbà náà ni Peteru sọ́dọ̀ Jesu, ó béèrè , "Olúwa, nígbà mélòó ni arákùnrin mi yóò ṣẹ̀ mi, èmi yóò dáríjì í? Tàbí ìgbà méje ni?"

22 Jesu dáhùn , "Mo fún , í ṣe ìgbà méje, ṣùgbọ́n ìgbà àádọ́rin méje.

23 "Nítorí náà, ìjọba ̀run dàbí ọba kan ó fẹ́ ṣe ìṣirò pẹ̀àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀. 24 ó ti ń ṣe èyí, a ajigbèsè kan sọ́dọ̀ rẹ̀ ó jẹ ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) tálẹ́ǹtì. 25 Nígbà í agbára láti san án, nígbà náà ni olúwa rẹ̀ pàṣẹ a ta òun àti ìyàwó àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀gbogbo ohun ó láti fi san gbèsè náà.

26 "Nígbà náà ni ọmọ ̀dọ̀ náà wólẹ̀ lórí eékún níwájú rẹ. Ó bẹ̀bẹ̀ , sùúrù fún mi, èmi yóò san gbogbo rẹ̀ fún . 27 Nígbà náà, ni olúwa ọmọ ̀dọ̀ náà ṣàánú fún un. Ó u sílẹ̀, ó fi gbèsè náà í.

28 "Ṣùgbọ́n ọmọ ̀dọ̀ náà ti jáde lọ, ó ̀kan nínú àwọn ọmọ ̀dọ̀ ẹgbẹ́ rẹ̀ ó jẹ ́ ọgọ́rùn-ún owó idẹ, ó gbé ọwọ́ e, ó fún un ọrùn, ó , San gbèsè o jẹ lójú ẹsẹ̀.’

29 "Ọmọ ̀dọ̀ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ náà wólẹ̀ lórí eékún níwájú rẹ̀, ò ń bẹ̀ ́ , sùúrù fún mi, èmi yóò san án fún .

30 "Ṣùgbọ́n òun kọ̀ fún un. Ó pàṣẹ a ọkùnrin náà, a ú sínú túbú títí yóò fi san gbèsè náà tán pátápátá. 31 Nígbà àwọn ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ohun ó ṣẹlẹ̀, inú wọn gidigidi, wọ́n lọ láti lọ sọ fún olúwa wọn, gbogbo ohun ó ṣẹlẹ̀.

32 "Nígbà olúwa rẹ̀ ọmọ ̀dọ̀ náà wọlé, ó fún un , Ìwọ ọmọ ̀dọ̀ búburú, níhìn-ín ni mo ti dárí gbogbo gbèsè rẹ ́ nítorí ìwọ bẹ̀ mi. 33 ha ṣe ̀tọ́ fún láti ṣàánú fún àwọn ẹlòmíràn, gẹ́gẹ́ èmi náà ti ṣàánú fún ? 34 ìbínú, olówó rẹ̀ fi í àwọn onítúbú lọ́wọ́ láti fi ìyà jẹ ́, títí yóò fi san gbogbo gbèsè èyí ti ó jẹ ́.

35 "Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni Baba mi ń bẹ ̀run yóò ṣe ẹnìkọ̀̀kan, ̀yin fi tọkàntọkàn dárí ji àwọn arákùnrin yín."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-