Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 2

Ìbẹ̀àwọn amòye

1 2.1: Lk 2.4-7; 1.5. Lẹ́yìn ìgbà a Jesu Bẹtilẹhẹmu ti Judea, ni àkókò ọba Herodu, àwọn amòye ti ìlà-oòrùn Jerusalẹmu. 2 2.2: Jr 23.5; Sk 9.9; Mk 15.2; Jh 1.49; Nu 24.17.Wọ́n si béèrè , "Níbo ni ẹni náà a í ṣe ọba àwọn Júù ? Àwa ti ìràwọ̀ rẹ̀ ìlà-oòrùn, a láti foríbalẹ̀ fún un."

3 Nígbà ọba Herodu gbọ́ èyí, ìdààmú a àti gbogbo àwọn ara Jerusalẹmu pẹ̀rẹ̀. 4 Nígbà ó pe àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin jọ, ó bi wọ́n léèrè níbi ti a ó gbé Kristi? 5 2.5: Jh 7.42.Wọ́n , "Bẹtilẹhẹmu ti Judea, èyí ni ohun wòlíì ti kọ ìwé rẹ̀ ,

6 2.6: Mik 5.2. " Ṣùgbọ́n ìwọ Bẹtilẹhẹmu, ilẹ̀ Judea,

ìwọ kéré láàrín àwọn ọmọ-aládé Juda;

nítorí láti inú rẹ ni Baálẹ̀ kan yóò ti jáde,

ẹni ti yóò ṣe ìtọ́Israẹli, àwọn ènìyàn mi.’ "

7 Nígbà náà ni Herodu ọba pe àwọn amòye náà ìkọ̀kọ̀, ó wádìí ni ọwọ́ wọn, àkókò náà gan an wọ́n kọ́kọ́ ìràwọ̀. 8 Ó rán wọn lọ Bẹtilẹhẹmu, ó , "lọ ṣe ìwádìí fínní fínní ti ọmọ náà a . Lẹ́yìn i, padà sọ fún mi, èmi náà le lọ foríbalẹ̀ fún un."

9 Nígbà wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ ọba, wọ́n ̀wọn pọ̀n, ó, ìràwọ̀ wọ́n ti láti ìhà ìlà-oòrùn , ó ṣáájú wọn, títí ó fi dúró lókè ibi ọmọ náà gbé . 10 Nígbà wọ́n ìràwọ̀ náà, ayọ̀ kún ọkàn wọn. 11 2.11: Mt 1.18; 12.46.wọ́n wọ inú ilé náà, wọn ọmọ ọwọ́ náà pẹ̀Maria ìyá rẹ̀, wọ́n wólẹ̀, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. Nígbà náà ni wọ́n ìṣúra wọn, wọ́n ta Jesu lọ́rẹ: wúrà, tùràrí àti òjìá. 12 2.12: Mt 2.22; Ap 10.22; Hb 11.7.Nítorí Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún wọn ojú àlá wọ́n ṣe padà tọ Herodu lọ mọ́, wọ́n gba ̀mìíràn lọ ìlú wọn.

A gbé Jesu sálọ Ejibiti

13 Nígbà wọn ti lọ, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu ojú àlá , "Dìde, gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀, ó sálọ Ejibiti. Dúró níbẹ̀ títí èmi yóò fi sọ fún , nítorí Herodu yóò ̀láti pa ọmọ ọwọ́ náà."

14 Nígbà náà ni ó dìde, ó ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ òru, ó lọ Ejibiti, 15 2.15: Ho 11.1.ó níbẹ̀ títí Herodu fi . Èyí jẹ́ ìmúṣẹ àsọtẹ́lẹ̀ ohun Olúwa sọ láti ẹnu wòlíì , "Mo pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti ."

16 Nígbà Herodu í àwọn amòye náà ti tan òun jẹ, ó bínú gidigidi, ó pàṣẹ a pa gbogbo àwọn ọmọkùnrin ó Bẹtilẹhẹmu àti ẹkùn rẹ̀ láti àwọn ọmọ ọdún méjì sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àkókò ó ti fi ̀sọ̀ ̀sọ̀ béèrè lọ́wọ́ àwọn amòye náà. 17 Nígbà náà ni èyí a ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wòlíì Jeremiah ṣẹ :

18 2.18: Jr 31.15. "A gbọ́ ohùn kan Rama,

ohùn réré ẹkún àti ̀fọ̀ ńlá,

Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀.

Ó kọ̀ láti gbìpẹ̀

nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ mọ́."

Ìpadà Nasareti

19 2.19: Mt 1.20; 2.13. Lẹ́yìn ikú Herodu, angẹli Olúwa fi ara hàn Josẹfu lójú àlá Ejibiti 20 Ó fún un , "Dìde gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ padà ilẹ̀ Israẹli, nítorí àwọn ń ̀ọmọ ọwọ́ náà láti pa ti ."

21 Nítorí náà, o dìde, ó gbé ọmọ ọwọ́ náà àti ìyá rẹ̀ ó ilẹ̀ Israẹli. 22 Ṣùgbọ́n nígbà ó gbọ́ Akelausi ni ó ń jẹ ọba Judea ipò Herodu baba rẹ̀, ó bẹ̀láti lọ ì bẹ̀. Nítorí Ọlọ́run ti kìlọ̀ fún un ojú àlá, ó padà, ó gba ẹkùn Galili lọ, 23 2.23: Lk 1.26; Mk 1.24.ó lọ í gbé ìlú a Nasareti. Nígbà náà ni èyí a sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì ìmúṣẹ: "A ó é ará Nasareti."

Veja também