Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 20

Òwe àwọn òṣìṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà

1 20.1: Mt 21.28,33. "Nítorí ìjọba ̀run dàbí ọkùnrin ó jẹ́ baálé kan, ó jíjáde lọ kùtùkùtù òwúrọ̀, ó gba àwọn alágbàṣe sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. 2 Òun pinnu láti san dínárì kan fún iṣẹ́ òòjọ́ kan. Lẹ́yìn èyí ó rán wọn lọ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀.

3 "wákàtí kẹta ọjọ́ ó ti ń kọjá níwájú ilé ìgbanisíṣẹ́, ó díẹ̀ nínú àwọn aláìríṣẹ́ wọ́n dúró ọjà. 4 Ó fún wọn , ̀yin pàápàá, lọ ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà mi, ó di òpin ọjọ́, èmi yóò san iye ti ó yẹ fún yín. 5 Wọ́n lọ.

"Ó tún jáde lọ́sàn án nǹkan wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsànán, ó túnṣe bákan náà. 6 Lọ́jọ́ kan náà wákàtí kọkànlá ọjọ́, ó tún jáde àárín ìlú, ó àwọn aláìríṣẹ́ mìíràn wọ́n dúró. Ó bi wọ́n , Èéṣe ̀yin í ṣiṣẹ́ gbogbo ọjọ́?’

7 "Wọ́n dáhùn , Nítorí ẹni yóò fún wa iṣẹ́ ṣe.

"Ó tún sọ fún wọn , ̀yin náà jáde lọ ṣiṣẹ́ pẹ̀nínú ọgbà àjàrà mi.

8 20.8: Le 19.13; De 24.15. "Nígbà ó di àṣálẹ́, ẹni ni ọgbà àjàrà sọ fún aṣojú rẹ̀ , Pe àwọn òṣìṣẹ́ náà, ó san owó iṣẹ́ wọn fún wọn, bẹ̀rẹ̀ láti ẹni ìkẹyìn lọ ti ìṣáájú.

9 "Nígbà àwọn ti a wákàtí kọkànlá ọjọ́ , ẹnìkọ̀̀kan gba owó dínárì kan. 10 Nígbà àwọn a gbà ṣiṣẹ́ lákọ̀́kọ́ fẹ́ gba owó tiwọn, èrò wọn ni àwọn yóò gba bẹ́̀ lọ, ṣùgbọ́n ẹnìkọ̀̀kan wọn gba owó dínárì kan. 11 wọ́n ti ń gbà á, wọ́n ń kùn onílẹ̀ náà, 12 , Wákàtí kan péré ni àwọn a gbà kẹ́yìn fi ṣiṣẹ́, ìwọ san iye kan náà fún wọn àti àwa náà ti a fi gbogbo ọjọ́ ṣiṣẹ́ nínú oòrùn gangan.

13 20.13: Mt 22.12; 26.50. "Ṣùgbọ́n ó ̀kan nínú wọn lóhùn , ̀rẹ́, aburú nínú nǹkan èmi ṣe yín. í ha ṣe ̀yin gbà láti ṣiṣẹ́ fún owó dínárì kan. 14 Ó , gba èyí í ṣé tìrẹ, ki ó máa lọ. Èmi fẹ́ láti fún ẹni ìkẹyìn gẹ́gẹ́ mo ti fi fún . 15 Àbí ó lòdì òfin èmi fún ẹnikẹ́ni owó mi mo yàn láti ṣe bẹ́̀? ni ìdí ìwọ láti bínú nítorí èmi ṣe ohun rere?

16 20.16: Lk 13.30; Mt 19.30; Mk 10.31. "Bẹ́̀ ni àwọn ẹni ìkẹyìn yóò di ẹni ìṣáájú, ẹni ìṣáájú yóò di ẹni ìkẹyìn."

Veja também