Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 23

Ìdí méje fún ìdájọ́

1 Nígbà náà ni Jesu fún ̀pọ̀ ènìyàn àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , 2 "Àwọn olùkọ́ òfin àti àwọn Farisi jókòó ipò Mose, 3 nítorí náà, gbọdọ̀ gbọ́ tiwọn, ṣe ohun gbogbo wọ́n sọ fún yín. Ṣùgbọ́n ṣe ohun wọ́n ṣe, nítorí àwọn pàápàá í ṣe ohun wọn kọ́ yín láti ṣe. 4 Wọ́n á di ẹrù wúwo ó ṣòro láti , wọ́n a gbé e le àwọn ènìyàn léjìká, ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn jẹ́ fi ìka wọn kan an.

5 23.5: Mt 6.1; 5.16; Ek 13.9; De 6.8; Mt 9.20. "Ohun gbogbo wọ́n ń ṣe, wọ́n ń ṣe é àwọn ènìyàn ba à wọn ni. Wọ́n ń sọ filakteri wọn di gbígbòòrò. Wọ́n tilẹ̀ ń bùkún ìṣẹ́aṣọ oyè wọn nígbà gbogbo ó ba à máa tóbi i. 6 Wọ́n fẹ́ ipò ọlá ibi àsè, àti níbi ìjókòó ìyàsọ́tọ̀ ni Sinagọgu. 7 Wọ́n fẹ́ ènìyàn máa wọn ọjà, àwọn ènìyàn máa wọ́n Rabbi.

8 23.8: Jk 3.1. "Ṣùgbọ́n a ṣe yín ni Rabbi, nítorí ẹnìkan ni Olùkọ́ yín, àní Kristi, ará ni gbogbo yín. 9 ṣe pe ẹnikẹ́ni baba yín ni ayé yìí, nítorí baba kan náà ni ó ń bẹ ̀run. 10 a ṣe yín Olùkọ́ nítorí Olùkọ́ kan ṣoṣo ni ̀yin , òun náà ni Kristi. 11 Ṣùgbọ́n ẹni ó pọ̀nínú yín, ni yóò jẹ́ ìránṣẹ́ yín. 12 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó gbé ara rẹ̀ ga ni a ó rẹ̀ sílẹ̀, ẹnikẹ́ni ó rẹ ara wọn sílẹ̀ ni a ó gbéga.

13 23.13: Lk 11.52. "Ègbé ni fún yín, ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ̀yin àgàbàgebè! ̀yin ìjọba ̀run mọ́ àwọn ènìyàn nítorí ̀yin tìkára yín wọlé, bẹ́̀ ni ̀yin jẹ́ àwọn ó fẹ́ wọlé ó wọlé. 23.13 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí wọlé. 14 Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ẹ̀yin àgàbàgebè! Àwọn tí wọ́n jẹ ilé àwọn opó rún, tí wọ́n sì ń gbàdúrà gígùn fún àṣehàn, nítorí èyí, ìjìyà wọn yóò pọ̀ púpọ̀ .

15 23.15: Ap 2.10; 6.5; 13.43. "Ègbé ni fún yín, ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ̀yin àgàbàgebè! Nítorí ̀yin rin ilẹ̀ àti òkun láti ẹnìkan lọ́kàn padà, ṣùgbọ́n ̀yin ń sọ ́ di ọmọ ̀run àpáàdì ìlọ́po méjì ju ̀yin pàápàá.

16 23.16-22: Mt 5.33-37; 15.14. "Ègbé ni fún yín, ̀yin afọ́ti ń fi ̀han afọ́! ó , Ẹnikẹ́ni ó ba fi tẹmpili búra nǹkan kan, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni fi wúrà inú tẹmpili búra, ó di ajigbèsè. 17 ̀yin aláìmòye afọ́: èwo ni ó ga , wúrà tàbí tẹmpili ó ń sọ wúrà di mímọ́? 18 Àti , ẹnikẹ́ni fi pẹpẹ búra, jámọ́ nǹkan, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó ba fi ̀bùn ó lórí rẹ̀ búra, ó di ajigbèsè. 19 ̀yin aláìmòye afọ́wọ̀nyí! Èwo ni ó pọ̀: ̀bùn ó lórí pẹpẹ ni tàbí pẹpẹ fúnra rẹ̀ ó sọ ̀bùn náà di mímọ́? 20 Nítorí náà ẹnikẹ́ni ó ń fi pẹpẹ búra, ó fi í búra àti gbogbo ohun ó lórí rẹ̀. 21 Àti , ẹni ó fi tẹmpili búra, ó fi í búra àti ẹni ń gbé inú rẹ̀. 22 Àti , ẹni ó fi ̀run búra, ó fi ìtẹ́ Ọlọ́run àti ẹni ó jókòó lórí rẹ̀ búra.

23 23.23-24: Lk 11.42; Le 27.30; Mt 6.8. "Ègbé ni fún yín ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ̀yin àgàbàgebè! Nítorí ̀yin ń gba ìdámẹ́wàá minti, dili àti kumini, ̀yin ti fi ohun ó ṣe pàtàkì jùlọ nínú òfin sílẹ̀ láìṣe, ìdájọ́, àánú àti ìgbàgbọ́. Wọ̀nyí ni ó tọ́ ̀yin ìbá ṣe, ̀yin fi wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀ láìṣe. 24 ̀yin afọ́ń fi afọ́mọ̀! tu kòkòrò-kantíkantí bọ́ yín lẹ́nu , gbé ìbákasẹ .

25 23.25-26: Lk 11.39-41; Mk 7.4. "Ègbé ni fún yín ̀yin Farisi àti ̀yin olùkọ́ òfin, ̀yin àgàbàgebè. ̀yin ń fọ òde ago àti àwo ṣùgbọ́n inú rẹ̀ kún fún ìrẹ́jẹ àti ̀gbin gbogbo. 26 Ìwọ afọ́Farisi, tètè kọ́ fọ inú ago àti àwo, gbogbo ago náà yóò di mímọ́.

27 23.27-28: Lk 11.44; Ap 23.3; Sm 5.9. "Ègbé ni fún yín ̀yin Farisi àti ̀yin olùkọ́ òfin, ̀yin àgàbàgebè. dàbí ibojì funfun ó dára wíwò, ṣùgbọ́n ó kún fún egungun ènìyàn àti fún ̀gbin àti ìbàjẹ́. 28 ̀yin gbìyànjú láti farahàn ènìyàn mímọ́, olódodo, lábẹ́ aṣọ mímọ́ yín ni ọkàn ó kún fún ìbàjẹ́ pẹ̀oríṣìíríṣìí àgàbàgebè àti ̀ṣẹ̀ .

29 23.29-32: Lk 11.47-48; Ap 7.51-53. "Ègbé ni fún yín ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ̀yin àgàbàgebè, nítorí ̀yin kọ́ ibojì àwọn wòlíì í ṣe ibojì àwọn olódodo ̀ṣọ́. 30 ̀yin , Àwa ìbá àsìkò àwọn baba wa, àwa ọwọ́ nínú ̀jẹ̀ àwọn wòlíì. 31 Ǹjẹ́ ̀yin ni ẹlẹ́rìí fún ara yín , ̀yin ni ọmọ àwọn ó pa àwọn wòlíì. 32 Àti , ̀yin ń tẹ̀ìṣísẹ̀ àwọn baba yín. ̀yin ń kún òsùwọ̀n ìwà búburú wọn òkè.

33 23.33: Mt 3.7; Lk 3.7. "̀yin ejò! ̀yin paramọ́lẹ̀! ̀yin yóò ti ṣe yọ nínú ̀bi ̀run àpáàdì? 34 Nítorí náà èmi yóò rán àwọn wòlíì àti àwọn ọlọ́gbọ́n ọkùnrin ó kún fún ̀mímọ́, àti àwọn akọ̀yín. ̀yin yóò pa àwọn kan nínú wọn nípa kíkàn wọ́n mọ́ àgbélébùú. ̀yin yóò fi pàṣán na àwọn ẹlòmíràn nínú Sinagọgu yín, ̀yin yóò ṣe inúnibíni wọn láti ìlú ìlú. 35 ̀yin jẹ̀bi gbogbo ̀jẹ̀ àwọn olódodo ta sílẹ̀ ayé, láti ̀jẹ̀ Abeli títí ̀jẹ̀ Sekariah ọmọ Berekiah ẹni pa nínú tẹmpili láàrín ibi pẹpẹ àti ibi ti mímọ́ fún Ọlọ́run. 36 Lóòótọ́ ni mo fún yín, gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò sórí ìran yìí.

37 23.37-39: Lk 13.34-35. "Jerusalẹmu, Jerusalẹmu, ìlú ó pa àwọn wòlíì, ó sọ òkúta lu àwọn a rán i. ̀pọ̀ ìgbà ni èmi ń fẹ́ àwọn ọmọ rẹ jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ àgbébọ̀ adìyẹ ti í dáàbò bo àwọn ọmọ rẹ̀ lábẹ́ ìyẹ́ rẹ, ṣùgbọ́n ̀yin kọ̀. 38 ó, a fi ilé yín sílẹ̀ fún yín ahoro. 39 Nítorí èmi sọ èyí fún yín, ̀yin yóò mi mọ́, títí ̀yin yóò fi sọ , Olùbùkún ni ẹni ń bọ̀ orúkọ Olúwa.’ "

Veja também