Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 26

Ìdìtẹ̀ mọ́ Jesu

1 26.1: Mt 7.28; 11.1; 13.53; 19.1. Nígbà Jesu ti parí ̀rọ̀ wọ̀nyí pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó fún wọn , 2 26.2-5: Mk 14.1-2; Lk 22.1-2; Jh 11.47-53."̀yin mọ̀ ọjọ́ méjì i, àjọ ìrékọjá yóò bẹ̀rẹ̀. Àti , a ó fi Ọmọ Ènìyàn wọn lọ́wọ́, a ó kàn mọ́ àgbélébùú."

3 àsìkò Jesu ń sọ̀rọ̀ yìí, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà ara wọn jọ ààfin olórí àlùfáà náà à ń Kaiafa. 4 Láti gbèrò àwọn ̀wọ́n yóò fi Jesu pẹ̀̀tàn, wọn pa á. 5 Ṣùgbọ́n wọ́n fohùn ṣọ̀kan , "í ṣe lásìkò àsè àjọ ìrékọjá, nítorí rògbòdìyàn yóò ṣẹlẹ̀."

A fi òróró kun Jesu lára Betani

6 26.6-13: Mk 14.3-9; Jh 12.1-8; Lk 7.36-38. Nígbà Jesu Betani ilé ọkùnrin à ń Simoni adẹ́tẹ̀. 7 ó ti ń jẹun, obìnrin kan sọ́dọ̀ rẹ̀ pẹ̀alabasita òróró ìkunra iyebíye, ó á i lórí.

8 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn i, inú wọn. Wọ́n , "Irú ìfowóṣòfò wo ni èyí? 9 Èéha ti ṣe, obìnrin yìí ìbá á owó púpọ̀, a fi owó náà fún àwọn aláìní."

10 Jesu ti mọ èrò ọkàn wọn, ó , "Èéṣe ti ̀yin fi ń obìnrin yìí lẹ́bi? Ó ṣe ohun ó dára fún mi. 11 ̀yin yóò àwọn aláìní láàrín yín nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n, ̀yin le mi nígbà gbogbo. 12 Nípa dída òróró ìkunra yìí mi lára, òun ń ṣe èyí fún ìsìnkú mi ni. 13 Lóòótọ́ ni mo fún yín, a ó máa ṣe ìrántí rẹ̀ nígbà gbogbo fún ìṣesí rẹ̀ yìí. Níbikíbi a ti wàásù ìyìnrere yìí gbogbo àgbáyé ni a ó ti sọ ìtàn ohun obìnrin yìí ṣe."

Judasi gbà láti fi Jesu hàn

14 26.14-16: Mk 14.10-11; Lk 22.3-6. Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn aposteli méjìlá ti à ń Judasi Iskariotu lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí àlùfáà. 15 26.15: Ek 21.32; Sk 11.12.Òun béèrè , "ni ̀yin yóò san fún mi mo fi Jesu yín lọ́wọ́?" Wọ́n fún un ọgbọ́n owó fàdákà. Ó gbà á. 16 Láti ìgbà náà lọ ni Judasi ti bẹ̀rẹ̀ i ̀láti á wọn lọ́wọ́.

Oúnjẹ alẹ́ ìkẹyìn

17 26.17-19: Mk 14.12-16; Lk 22.7-13. ọjọ́ kìn-ín-ní àjọ àìwúkàrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tọ Jesu , "Níbo ni ìwọ fẹ́ a pèsè sílẹ̀ láti jẹ àsè ìrékọjá?"

18 26.18: Mt 26.45; Jh 7.6; 12.23; 13.1; 17.1. Jesu dáhùn , "wọ ìlú lọ, ̀yin yóò ọkùnrin kan, fún un , Olùkọ́ wa , àkókò mi ti . Èmi yóò jẹ àsè ìrékọjá pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi ilé rẹ.’ " 19 26.19: Mt 21.6; De 16.5-8.Nítorí náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà ṣe gẹ́gẹ́ Jesu ti sọ fún wọn. Wọ́n tọ́oúnjẹ àsè ti ìrékọjá níbẹ̀.

20 26.20-24: Mk 14.17-21; Lk 22.14,21-23; Jh 13.21-30. àṣálẹ́ ọjọ́ kan náà, Jesu ti jókòó pẹ̀àwọn méjìlá, 21 nígbà wọ́n ń jẹun, ó , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, ̀kan nínú yín yóò fi hàn."

22 Ìbànújẹ́ bo ọkàn wọn nígbà wọ́n gbọ́ èyí. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ bi í , "Olúwa, èmi ni ?"

23 Jesu dáhùn , "Ẹni ti ó mi tọwọ́ bọ inú àwo, ni yóò fi mi hàn. 24 Ọmọ Ènìyàn ń lọ a ti kọ̀nípa rẹ̀: ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin náà lọ́wọ́ ẹni a ó ti fi Ọmọ Ènìyàn hàn! Ìbá kúkú sàn fún ẹni náà, a ."

25 Judasi, ẹni ó fi í hàn pẹ̀béèrè , "Rabbi, èmi ni ?"

Jesu a lóhùn , "Ìwọ i."

26 26.26-29: Mk 14.22-25; Lk 22.17-19; 1Kọ 10.16; 11.23-26; Mt 14.19; 15.36. wọ́n ti ń jẹun, Jesu ìwọ̀n àkàrà kékeré kan, lẹ́yìn ó ti gbàdúrà i, ó ú, Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Ó , "Gbà, jẹ; nítorí èyí ni ara mi."

27 Bákan náà, ó ago wáìnì, ó dúpẹ́ fún un, ó gbé e fún wọn. Ó , "gbogbo yín mu nínú rẹ̀. 28 Nítorí èyí ni ̀jẹ̀ mi májẹ̀tuntun, a ta sílẹ̀ fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀ ènìyàn.

Veja também