Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 4

Ìdánwò Jesu

1 4.1-11: Mk 1.12-13; Lk 4.1-13; Hb 2.18; 4.15. Nígbà náà ni ̀Mímọ́ darí Jesu ijù láti dán an láti ọwọ́ èṣù. 2 4.2: El 34.28; 1Ọb 19.8.Lẹ́yìn Òun ti gbààwẹ̀ ogójì ̀sán àti ogójì òru, ebi ń pa á. 3 Nígbà náà ni olùdánwò tọ̀ ́ , ó , "ìwọ ṣe Ọmọ Ọlọ́run, pàṣẹ òkúta wọ̀nyí di àkàrà."

4 4.4: De 8.3. Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "A ti kọ ìwé rẹ̀ : Ènìyàn yóò láààyè nípa àkàrà nìkan, ṣe nípa gbogbo ̀rọ̀ ti ó ti ẹnu Ọlọ́run jáde .’ "

5 4.5: Mt 27.53; Ne 11.1; Da 9.24; If 21.10. Lẹ́yìn èyí ni èṣù gbé e lọ ìlú mímọ́ náà; ó gbé e ibi ṣóńṣó tẹmpili. 6 4.6: Sm 91.11-12.Ó , "ìwọ̀ jẹ́ Ọmọ Ọlọ́run, bẹ́ sílẹ̀ fún ara rẹ. A à ti kọ̀rẹ̀ ,

" Yóò pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí tìrẹ

wọn yóò gbé sókè ni ọwọ́ wọn

ìwọ ó ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gbún òkúta.’ "

7 4.7: De 6.16. Jesu dalóhùn, "A à ti kọ ́ , Ìwọ gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run rẹ .’ "

8 Lẹ́̀kan i, èṣù gbé e lọ sórí òkè gíga, ó fi gbogbo ilẹ̀ ọba ayé àti gbogbo ògo wọn hàn án. 9 Ó fún un , "Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi yóò fi fún , ìwọ foríbalẹ̀ o sìn mi."

10 4.10: De 6.13; Mk 8.33. Jesu fún un , "Padà kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Nítorí a ti kọ ́ , Olúwa Ọlọ́run rẹ ni ìwọ ó fi orí balẹ̀ fún, òun nìkan ṣoṣo ni ìwọ máa sìn.’ "

11 4.11: Mt 26.53; Lk 22.43. Nígbà náà ni èṣù fi í sílẹ̀ lọ, àwọn angẹli tọ̀ ́ , wọ́n ṣe ìránṣẹ́ fún un.

Veja também