Publicidade

Mateus 9

Jesu arọ láradá

1 Jesu bọ́ sínú ọkọ̀, ó rékọjá odò lọ ìlú abínibí rẹ̀, 2 àwọn ọkùnrin kan gbé arọ kan tọ̀ ́ lórí àkéte rẹ̀. Nígbà Jesu ìgbàgbọ́ wọn, ó fún arọ náà , "Ọmọ tújúká, a dárí ̀ṣẹ̀ rẹ ́."

3 Nígbà yìí ni àwọn olùkọ́ òfin fún ara wọn , "Ọkùnrin yìí ń sọ̀rọ̀-òdì!"

4 Jesu mọ̀ èrò inú wọn, ó , "Nítorí kín ni ̀yin ṣe ń ro búburú nínú yín? 5 Èwo ni ó rọrùn : láti , A dárí ̀ṣẹ̀ rẹ ,tàbí , Dìde, o máa rìn? 6 Ṣùgbọ́n ̀yin ó mọ̀ Ọmọ Ènìyàn agbára ayé láti dárí ̀ṣẹ̀ ni." Ó fún arọ náà , "Dìde, gbé àkéte rẹ, o máa lọ ilé rẹ." 7 Ọkùnrin náà dìde, ó lọ ilé rẹ̀. 8 Nígbà ìjọ ènìyàn í ẹnu wọ́n, wọ́n yin Ọlọ́run lógo, ti ó fi irú agbára báyìí fún ènìyàn.

Ìpè Matiu

9 Jesu ti ń rékọjá láti ibẹ̀ lọ, o ọkùnrin kan ti à ń Matiu, ó jókòó ibùdó àwọn agbowó òde, ó fún un , "Máa tọ̀ lẹ́yìn," Matiu dìde, ó ń tọ̀ ́ lẹ́yìn.

10 Ó ṣe, Jesu jókòó ti ó ń jẹun nínú ilé Matiu, kíyèsi i, ̀pọ̀ àwọn agbowó òde àti ẹlẹ́ṣẹ̀ , wọ́n a jẹun pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 11 Nígbà àwọn Farisi i, wọ́n fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Èéṣe olùkọ́ yín fi ń àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun pọ̀?"

12 Ṣùgbọ́n nígbà Jesu gbọ́ èyí, ó fún wọn , "Àwọn ara wọ́n le oníṣègùn ṣe àwọn ara wọn . 13 Ṣùgbọ́n lọ kọ́ ohun ti èyí túmọ̀ : Àánú ni èmi ń fẹ́, í ṣe ẹbọ,nítorí èmi láti pe àwọn olódodo, ṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀."

Ìbéèrè nípa àwẹ̀ lọ́wọ́ Jesu

14 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu tọ̀ ́ láti béèrè , "Èéṣe àwa àti àwọn Farisi fi ń gbààwẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ gbààwẹ̀?"

15 Jesu dáhùn , "Àwọn ọmọ ilé ìyàwó ha le máa ṣọ̀fọ̀, nígbà ọkọ ìyàwó ń bẹ lọ́dọ̀ wọn? Ṣùgbọ́n ọjọ́ ń bọ̀ nígbà a ó gba ọkọ ìyàwó lọ́wọ́ wọn; nígbà náà ni wọn yóò gbààwẹ̀.

16 "ẹni ń fi ìrépé aṣọ tuntun lẹ ògbólógbòó ̀; nítorí èyí a fi lẹ̀ ́ yóò ya ojú lílẹ̀, aṣọ náà yóò ya púpọ̀ i ju ti ìṣáájú lọ. 17 Bẹ́̀ ni ẹni fi ọtí tuntun sínú ògbólógbòó ìgò-awọ; a ṣe bẹ́̀, ìgò-awọ yóò bẹ́, ọtí á jáde, ìgò-awọ á ṣègbé. Ṣùgbọ́n ọtí tuntun ni wọn í fi sínú ìgò-awọ tuntun àwọn méjèèjì a ṣe déédé."

Ọmọbìnrin àti obìnrin onísun-ẹ̀jẹ̀

18 ó ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí fún wọn, kíyèsi i, ìjòyè kan tọ̀ ́ , ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀ , "Ọmọbìnrin mi nísinsin yìí, ṣùgbọ́n fi ọwọ́ rẹ̀ e, òun yóò ." 19 Jesu dìde ó a lọ àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.

20 kíyèsi i, obìnrin kan ti ó ìsun ̀jẹ̀ ọdún méjìlá, ó lẹ́yìn rẹ̀, ó fi ọwọ́ kan ìṣẹ́aṣọ rẹ̀. 21 Nítorí ó nínú ara rẹ̀ , "mo à le fi ọwọ́ kan ìṣẹ́aṣọ rẹ̀, ara mi yóò ."

22 Nígbà Jesu ara rẹ̀ padà ó i, ó , "Ọmọbìnrin, tújúká, ìgbàgbọ́ rẹ láradà." A obìnrin náà láradá ni wákàtí kan náà.

23 Nígbà Jesu i ilé ìjòyè náà, ó àwọn afunfèrè àti ̀pọ̀ ènìyàn ó ń pariwo. 24 Ó fún wọn , "máa lọ; nítorí ọmọbìnrin náà , sísùn ni ó sùn." Wọ́n fi i rín ̀rín ẹlẹ́. 25 Ṣùgbọ́n nígbà a ti àwọn ènìyàn jáde, ó wọ ilé, ó ọmọbìnrin náà ọwọ́ sókè; bẹ́̀ ni ọmọbìnrin náà dìde. 26 Òkìkí èyí kàn gbogbo ilẹ̀ náà.

Jesu wo afọ́àti odi sàn

27 Nígbà Jesu jáde níbẹ̀, àwọn ọkùnrin afọ́méjì tọ̀ ́ lẹ́yìn, wọ́n ń kígbe sókè , "Ṣàánú fún wa, ìwọ ọmọ Dafidi."

28 Nígbà ó wọ̀ ilé, àwọn afọ́náà tọ̀ ́ , Jesu bi wọ́n , "̀yin gbàgbọ́ mo le ṣe èyí?"

Wọn fún un , "Bẹ́̀ ni Olúwa, ìwọ ṣe é."

29 Ó fi ọwọ́ wọ́n ojú, ó , "ó fún yín gẹ́gẹ́ ìgbàgbọ́ yín." 30 Ojú wọn ; Jesu kìlọ̀ fún wọn gidigidi, , "Kíyèsi i, ṣe jẹ́ ẹnìkan ó mọ̀ nípa èyí." 31 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n lọ, wọ́n ròyìn rẹ̀ gbogbo ìlú náà .

32 wọ́n ń jáde lọ, ó wọ́n ọkùnrin odi kan ó ̀èṣù tọ Jesu . 33 Nígbà a ̀èṣù náà jáde, ọkùnrin ó ya odi fọhùn. Ẹnu ya àwọn ènìyàn, wọ́n , "A irú èyí Israẹli."

34 Ṣùgbọ́n àwọn Farisi , "Agbára olórí àwọn ̀èṣù ni ó fi ń àwọn ̀èṣù jáde."

Àwọn Alágbàṣe Kéré

35 Jesu rìn gbogbo ìlú ńlá àti ìletò , ó ń kọ́ni nínú Sinagọgu wọn, ó ń wàásù ìyìnrere ìjọba ọrun, ó ń ṣe ìwòsàn ààrùn àti gbogbo àìsàn ara àwọn ènìyàn. 36 Nígbà ó ̀pọ̀ ènìyàn, àánú wọn ṣe é, nítorí àárẹ̀ wọn, wọn ìrànlọ́wọ́, àwọn àgùntàn olùṣọ́. 37 Nígbà náà ni ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Lóòótọ́ ni ìkórè pọ̀ ṣùgbọ́n àwọn alágbàṣe nǹkan. 38 Nítorí náà, gbàdúrà Olúwa ìkórè ó rán àwọn alágbàṣe sínú ìkórè rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-