Pular para o conteúdo
Publicidade

Romanos 10

12 10.12: Ro 3.22,29; Ga 3.28; Kl 3.11; Ap 10.36.Nítorí si ìyàtọ̀ nínú Júù àti Helleni: nítorí Olúwa kan náà ni Olúwa gbogbo wọn, o si pọ̀ ni ọrọ̀ fún gbogbo àwọn ti ń pe e. 13 "Ẹnikẹ́ni ó à ti pe orúkọ Olúwa ni a ó gbàlà."

14 Ǹjẹ́ wọn ó ha ti ṣe pe ẹni wọn gbàgbọ́? Wọn ó ha ti ṣe gba ẹni wọn gbúròó rẹ̀ gbọ́? Wọn o ha ti ṣe gbọ́ láìsí oníwàásù? 15 10.15: Isa 52.7.Wọ́n ó ha ti ṣe wàásù, ṣe a rán wọn? Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Ẹsẹ̀ àwọn ń wàásù ìyìnrere àlàáfíà ti dára , àwọn ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ohun rere!"

16 10.16: Isa 53.1; Jh 12.38. Ṣùgbọ́n í ṣe gbogbo wọn ni ó gbọ́ ti ìyìnrere. Nítorí Isaiah , "Olúwa, ta ni ó gba ìyìn wa gbọ́?" 17 Ǹjẹ́ nípa gbígbọ́ ni ìgbàgbọ́ ti í , àti gbígbọ́ nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run.

Veja também