Publicidade

Romanos 14

Aláìlera àti alágbára

1 gba ẹni ó ṣe àìlera ìgbàgbọ́ mọ́ra, ṣe tọpinpin ìṣeyèméjì rẹ̀. 2 Ẹnìkan gbàgbọ́ òun máa jẹ ohun gbogbo: ṣùgbọ́n ẹlòmíràn ó jẹ́ aláìlera ìgbàgbọ́ ń jẹ ewébẹ̀ nìkan. 3 ẹni ń jẹ ohun gbogbo ṣe kẹ́gàn ẹni jẹ; ẹni jẹ ohun gbogbo ó ṣe ẹni ń jẹ lẹ́bi nítorí Ọlọ́run ti gbà á. 4 Ta ni ìwọ láti ọmọ ̀dọ̀ ẹlòmíràn lẹ́jọ́? Lójú olúwa tirẹ̀ ni òun dúró, tàbí ṣubú. Òun yóò dúró nítorí Ọlọ́run agbára láti òun dúró.

5 Ẹnìkan bu ọlá fún ọjọ́ kan ju òmíràn; ẹlòmíràn bu ọlá fún ọjọ́ gbogbo bákan náà. olúkúlùkù ó ara rẹ̀ lójú inú ara rẹ̀. 6 Ẹni ó ya ọjọ́ kan ̀tọ̀, ó ń á sọ́tọ̀ fún Olúwa. Ẹni ó ń jẹ ẹran, ó ń jẹ ẹran fún Olúwa, nítorí òun náà dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run; ẹni jẹ ẹran, jẹ ẹran fún Olúwa, òun náà dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run. 7 Nítorí ẹnìkan ó láààyè fún ara rẹ̀, bẹ́̀ ni ẹni ó fún ara rẹ̀. 8 a láààyè, a láààyè fún Olúwa; a , a fún Olúwa. Nítorí náà, a láààyè, tàbí a , ti Olúwa ni àwa i ṣe. 9 Nítorí ìdí èyí náà ni Kristi ṣe , ó tún , ó le jẹ́ Olúwa òkú àti alààyè.

10 Èéṣe nígbà náà ìwọ fi ń arákùnrin tàbí arábìnrin rẹ lẹ́jọ́? Tàbí èéṣe ìwọ fi ń gàn wọn? Nítorí gbogbo wa ni yóò dúró níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Ọlọ́run. 11 A ti kọ ìwé rẹ̀ :

" Níwọ́n ìgbà mo láààyè,ni Olúwa ,

gbogbo eékún ni yóò wólẹ̀ fún mi;

gbogbo ahọ́n ni yóò jẹ́wọ́ fún Ọlọ́run.’ "

12 Ǹjẹ́ nítorí náà, olúkúlùkù wa ni yóò jíyìn ara rẹ̀ fún Ọlọ́run.

13 Nítorí náà, ṣe tún jẹ́ a máa ara wa lẹ́jọ́ mọ́. Ṣùgbọ́n dípò bẹ́̀, pinu nínú ọkàn yín láti ṣe fi ohun ìkọ̀sẹ̀ tàbí òkúta ìdìgbòlù kankan ̀arákùnrin tàbí arábìnrin yín. 14 Mo mọ̀ dájú gbangba ẹni ó nínú Jesu Olúwa , ohun ṣe àìmọ́ fún ara rẹ̀. Ṣùgbọ́n ẹni ó ka ohunkóhun àìmọ́, òun ni ó ṣe àìmọ́ fún. 15 inú arákùnrin tàbí arábìnrin rẹ ba bàjẹ́ nítorí oúnjẹ rẹ, ìwọ rìn nínú ìfẹ́ mọ́. ṣe fi oúnjẹ rẹ sọ ẹni Kristi fún di ẹni ègbé. 16 Nítorí náà, ṣe jẹ́ a máa sọ̀rọ̀ ohun mọ̀ rere búburú. 17 Nítorí ìjọba ̀run í ṣe jíjẹ àti mímu, ṣe nípa ti òdodo, àlàáfíà àti ayọ̀ nínú ̀Mímọ́, 18 nítorí ẹni ó sin Kristi nínú nǹkan wọ̀nyí ni ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run, ó ìyìn lọ́dọ̀ ènìyàn.

19 Nítorí náà, jẹ́ a ṣa gbogbo ipá wa láti máa lépa àlàáfíà, àti ohun àwa yóò fi gbé ara wa . 20 ṣe bi iṣẹ́ Ọlọ́run ṣubú nítorí oúnjẹ. Gbogbo oúnjẹ ni ó mọ́, ṣùgbọ́n ohun búburú ni fún ẹni náà ó jẹ ohunkóhun ó le ẹlòmíràn kọsẹ̀. 21 Ó dára a tilẹ̀ jẹ ẹran tàbí mu wáìnì tàbí ṣe ohunkóhun yóò arákùnrin tàbí arábìnrin rẹ ṣubú.

22 Nítorí náà, ohun ìwọ gbàgbọ́ nípa gbogbo nǹkan wọ̀nyí, pa á mọ́ àárín ìwọ àti Ọlọ́run. Alábùkún fún ni ẹni náà ara rẹ̀ lẹ́bi nínú ohun ó yàn. 23 Ṣùgbọ́n ẹni ó ṣe iyèméjì, ó jẹ̀bi ó ba jẹ ́, nítorí jíjẹ ́ rẹ̀ ti inú ìgbàgbọ́ ; bẹ́̀ ni, ohun gbogbo ti inú ìgbàgbọ́ , ̀ṣẹ̀ ni.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-