Publicidade

Romanos 16

Ìkíni

1 Mo fi Febe arábìnrin wa le yin lọ́wọ́, ẹni ó jẹ́ díákónì nínú ìjọ ó Kenkerea. 2 Mo rọ̀ yín gbà á orúkọ Olúwa, ó ti yẹ fún àwọn ènìyàn mímọ́, ̀yin ó ràn án lọ́wọ́ gbogbo ̀, nítorí òun jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn àti fún èmi náà pẹ̀.

3 Priskilla àti Akuila, àwọn ó ti jẹ́ alábáṣiṣẹ́pọ̀ mi nínú Kristi Jesu. 4 Àwọn wọ́n ti fi ̀wọn wéwu nítorí mi. í ṣe èmi nìkan àti gbogbo àwọn ìjọ àwọn aláìkọlà ń dúpẹ́ lọ́wọ́ wọn.

5 ìjọ ń péjọpọ̀ ilé wọn.

Epenetu ̀rẹ́ mi ̀wọ́n, òun ni ẹni àkọ́kọ́ ó di ti Kristi orílẹ̀-èdè Asia.

6 Maria, ẹni ó ṣe làálàá púpọ̀ lórí wa.

7 Androniku àti Junia, àwọn ìbátan mi wọ́n ̀wọ̀n pẹ̀mi. Àwọn wọ̀nyí ìtayọ láàrín àwọn aposteli, wọ́n ti nínú Kristi ṣáájú mi.

8 Ampliatu, ẹni ó jẹ́ olùfẹ́ mi nínú Olúwa.

9 Urbani, alábáṣiṣẹ́pọ̀ wa nínú Kristi àti olùfẹ́ mi ̀wọ́n Staki.

10 Apelle, ẹni a mọ̀ dájú nínú Kristi.

gbogbo àwọn ará nílé Aristobulu.

11 Herodioni, ìbátan mi.

gbogbo àwọn ará nílé Narkissu wọ́n nínú Olúwa.

12 Trifena àti Trifosa, àwọn obìnrin wọ́n ṣe iṣẹ́ takuntakun nínú Olúwa.

Persi ̀rẹ́ mi ̀wọ́n, obìnrin mìíràn ó ṣe iṣẹ́ takuntakun nínú Olúwa.

13 Rufusi, ẹni a yàn nínú Olúwa, àti ìyá rẹ̀ àti ẹni ó ti jẹ́ ìyá fún èmi náà pẹ̀.

14 Asinkritu, Flegoni, Herma, Patroba, Hermesi àti àwọn arákùnrin àti arábìnrin ó pẹ̀wọn.

15 Filologu, àti Julia, Nereu, àti arábìnrin rẹ̀, àti Olimpa, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ ó pẹ̀wọn.

16 fi ìfẹnukonu mímọ́ ara yín.

Gbogbo ìjọ Kristi yín.

17 Èmí rọ̀ yín, ara, máa sọ àwọn ń fa ìyapa, àti àwọn ń ohun ìkọ̀sẹ̀ ̀yín, èyí ó lòdì ̀kọ́ ̀yin kọ́. kúrò ̀dọ̀ wọn. 18 Nítorí irú àwọn ẹni bẹ́̀ sin Kristi Olúwa wa, ṣe ikùn ara wọn. Nípa ̀rọ̀ rere àti ̀rọ̀ dídùndídùn ni wọ́n fi ń àwọn aláìmọ̀kan ọkàn padà. 19 Nítorí ìgbọ́ràn yín tànkálẹ̀ ibi gbogbo, nítorí náà mo ayọ̀ lórí yín; ṣùgbọ́n èmi fẹ́ jẹ́ ọlọ́gbọ́n ohun ó ṣe rere, ṣe òpè ohun í ṣe búburú.

20 Ọlọ́run àlàáfíà yóò tẹ Satani mọ́lẹ̀ àtẹ́lẹsẹ̀ yín lọ́́lọ́́ yìí.

Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa ó pẹ̀yín.

21 Timotiu alábáṣiṣẹ́ mi, àti Lukiu, àti Jasoni, àti Sosipateru, àwọn ìbátan mi, yín.

22 Èmi Tertiu ń kọ lẹ́yìí, yín nínú Olúwa.

23 Gaiusi, ẹni èmi àti gbogbo ìjọ gbádùn ìtọ́wa ó ṣe náà fi ìkíni ránṣẹ́.

Erastu, ẹni ó jẹ́ olùtọ́ìṣúra ìlú, àti arákùnrin wa Kuartu fi ìkíni wọn ránṣẹ́.

25 Ǹjẹ́ fún ẹni ó agbára láti fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ nípa ìyìnrere mi àti ìpolongo Jesu Kristi, gẹ́gẹ́ ìṣípayá ohun ìjìnlẹ̀ a ti pamọ́ láti ìgbà ayérayé, 26 ṣùgbọ́n, nísinsin yìí, a ti fihàn nípa ìwé mímọ́ àwọn wòlíì, àti gẹ́gẹ́ àṣẹ Ọlọ́run ayérayé pa, gbogbo orílẹ̀-èdè le ìgbọ́ràn ó láti inú ìgbàgbọ́; 27 ògo fún Ọlọ́run, ẹnìkan ṣoṣo ọgbọ́n í ṣe tirẹ̀ nípa Jesu Kristi títí láé! Àmín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-