Publicidade

Romanos 8

Ìyè nípasẹ̀ ̀

1 8.1: Ro 5.16. Nítorí náà, ìdálẹ́bi nísinsin yìí fún àwọn ó nínú Kristi Jesu, àwọn rìn nípa ti ara, ṣe nípa ti ̀. 2 8.2: 1Kọ 15.45; Ro 6.14,18.Nítorí nípasẹ̀ òfin ti ̀ìyè nínú Kristi Jesu ti sọ di òmìnira kúrò lọ́wọ́ òfin ̀ṣẹ̀ àti ikú. 3 8.3: Ap 13.39; Hb 7.18; 10.1-2; Fp 2.7; Hb 2.14.Nítorí ohun òfin ṣe, ó ti jẹ aláìlera nítorí ara, Ọlọ́run rán ọmọ òun tìkára rẹ̀ àwòrán ara ̀ṣẹ̀, ó di ̀ṣẹ̀; àti bi ẹbọ fún ̀ṣẹ̀, ó ̀ṣẹ̀ lẹ́bi nínú ara, 4 8.4: Ro 3.31; Ga 5.16,25.a òdodo òfin ṣẹ, nínú wa, nítorí àwa gẹ́gẹ́ ohun ti ara, ṣe gẹ́gẹ́ ohun ti ̀.

5 8.5: Ga 5.19-25. Àwọn ń gbe nípa ti ara, wọn a máa ronú ohun ti ara; ṣùgbọ́n àwọn ti ń gbe nípa ti ̀, wọn a máa ronú ohun ti ̀. 6 8.6: Ro 6.21; 8.13,27; Ga 6.8.Nítorí èrò ti ara ikú ni; ṣùgbọ́n èrò ti ̀ni ìyè àti àlàáfíà. 7 Nítorí èrò ti ara ̀ni Ọlọ́run, nítorí í tẹríba fún òfin Ọlọ́run, òun tilẹ̀ le ṣe e. 8 8.8: Ro 7.5.Ìdí nìyìí àwọn ó lábẹ́ àkóso ara ̀ṣẹ̀, le è tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn.

9 8.9: 1Kọ 3.16; 6.19; 2Kọ 6.16; 2Tm 1.14. Ṣùgbọ́n ẹyin nínú ti ara, ṣe nínú ti ̀, ó ṣe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín. Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ̀Kristi, òun nínú ẹni tirẹ̀. 10 8.10: Ga 2.20; Ef 3.17.ó tilẹ̀ jẹ́ Kristi ń gbé inú yín síbẹ̀síbẹ̀, ara yín jẹ́ òkú nítorí ̀ṣẹ̀; ṣùgbọ́n ̀mímọ́ ń gbé inú yín yóò fún yín ìyè, nítorí ó ti fún un yín òdodo. 11 8.11: Jh 5.21.Àti , ̀Ọlọ́run, ẹni ó Jesu kúrò nínú òkú ń gbé inú yín, ẹni ó Kristi Jesu dìde kúrò nínú òkú, yóò fi ̀rẹ̀ ń gbé inú yín sọ ara kíkú yín di ààyè pẹ̀.

12 Nítorí náà ará a ni ojúṣe láti ṣe, ṣùgbọ́n í ṣe nípa nǹkan ara, a ó fi máa gbé nípa ti ara. 13 8.13: Ro 8.6; Kl 3.5.Nítorí ̀yin ń tẹ̀, ̀ṣẹ̀ ti ara ̀yin yóò sọnù, ó ṣègbé, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ń gbé nípa ti ara, ̀yin yóò , ṣùgbọ́n ̀yín ń gbé nípa ti ̀, ó pa iṣẹ́ ti ara run, ̀yin yóò .

14 8.14: Ga 5.18. Nítorí , iye àwọn ̀Ọlọ́run ń darí ni ọmọ Ọlọ́run. 15 8.15: Ro 9.4; Ga 4.5-7; Mk 14.36.Nítorí ̀yin tún gba ̀ẹrú láti máa bẹ̀mọ́; ṣùgbọ́n ̀yin gba ̀ìsọdọmọ, nípa èyí àwa fi ń "Ábbà, Baba." 16 8.16: Ap 5.32.Nítorí ̀mímọ́ ń sọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ nínú ọkàn wa, ó ń sọ fún wa , nítòótọ́, àwa jẹ́ ọmọ Ọlọ́run. 17 8.17: Ga 3.29; 4.7; 2Kọ 1.5,7; 2Tm 2.12; 1Pt 4.13.Níwọ́n ìgbà a jẹ́ ọmọ rẹ̀, ǹjẹ́ ajogún ni àwa, ajogún Ọlọ́run, àti àjùmọ̀jogún pẹ̀Kristi, ó ṣe àwa jìyà, a le ṣe lógo pẹ̀rẹ̀.

Ìgbádùn ń bọ̀ àti ìjìyà ìsìn yìí

18 8.18: 2Kọ 4.17; Kl 3.4; 1Pt 5.1. Síbẹ̀síbẹ̀, ìyà a ń jẹ nísinsin yìí jámọ́ nǹkan nígbà a fiwé ògo yóò fún wa ìkẹyìn. 19 8.19: 1Pt 1.7,13; 1Jh 3.2.Nítorí ̀ń dúró ìfojúsọ́de ìfihàn àwọn ọmọ Ọlọ́run. 20 8.20: On 1.2.Nítorí a tẹrí ̀ba fún asán, í ṣe òun ti fẹ́, ṣùgbọ́n nípa ìfẹ́ ẹni ó tẹ orí rẹ̀ ba ìrètí. 21 8.21: Ap 3.21; Ro 6.21; 2Pt 3.13; If 21.1.Nítorí a ó sọ ̀tìkára rẹ̀ di òmìnira kúrò nínú ẹrú ìdíbàjẹ́, òmìnira ògo àwọn ọmọ Ọlọ́run.

22 8.22: Jr 12.4,11. Nítorí àwa mọ̀ gbogbo ̀ni ó jùmọ̀ ń kérora ó ń rọbí pọ̀ títí di ìsinsin yìí. 23 8.23: 2Kọ 1.22; 5.2,4; Ga 5.5.í ṣe àwọn nìkan, ṣùgbọ́n àwa tìkára wa pẹ̀, a ni àkóso ̀, àní àwa tìkára wa ń kérora nínú ara wa, àwa ń dúró de ìsọdọmọ àní ìdáǹdè ara wa. 24 8.24: 2Kọ 5.7; Hb 11.1.Nítorí nípa ìrètí ni a fi gbà , ṣùgbọ́n ìrètí a í ṣe ìrètí nítorí ta ni ń retí ohun ó ? 25 Ṣùgbọ́n àwa ń retí èyí àwa , ǹjẹ́ àwa ń fi sùúrù dúró é.

26 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ̀pẹ̀ń ran àìlera wa lọ́wọ́: nítorí a mọ a ti ń gbàdúrà gẹ́gẹ́ ó ti yẹ, ṣùgbọ́n ̀tìkára rẹ̀ ń fi ìrora a le fi ẹnu sọ bẹ̀bẹ̀ fún wa. 27 8.27: Sm 139.1-2; Lk 16.15; If 2.23; Ro 8.6,34.Ẹni ó ń inú ọkàn , ó mọ ohun ti ̀, nítorí ó ń bẹ̀bẹ̀ fún àwọn ènìyàn mímọ́ gẹ́gẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run.

28 Àwa mọ̀ ohun gbogbo ni ó ń ṣiṣẹ́ pọ̀ rere fún àwọn ó fẹ́ Ọlọ́run, àní fún àwọn ẹni a gẹ́gẹ́ ìpinnu rẹ̀. 29 8.29: Ro 9.23; 11.2; 1Pt 1.2,20; Ef 1.5,11.Nítorí àwọn ẹni ó mọ̀ tẹ́lẹ̀, ni ó yàn tẹ́lẹ̀ láti àwòrán ọmọ rẹ̀, òun jẹ́ àkọ́láàrín àwọn arákùnrin púpọ̀. 30 Àti lẹ́yìn òun ti sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó sọ di aláìjẹ̀bi lẹ́yìn èyí, ó fi rere Kristi kún inú ọkàn wa. Lékè gbogbo rẹ̀, ó fún wa ìdúró rere pẹ̀rẹ̀, ó pinu ògo rẹ̀ fún wa.

Jíju aṣẹ́gun lọ

31 8.31: Sm 118.6. ni àwa yóò nísinsin yìí nǹkan ìyanu wọ̀nyí? Ọlọ́run pẹ̀wa, ta ni yóò kọjú ìjà wa? 32 8.32: Jh 3.16; Ro 4.25; 5.8.Níwọ̀n ìgbà Ọlọ́run ti fi Ọmọ rẹ̀ fún wa, ǹjẹ́ ó ha tún le ṣòro fún un láti fún wa ohunkóhun ? 33 8.33: Lk 18.7; Isa 50.8-9.Ta ni ẹni náà ó wa lẹ́bi, àwa ẹni Ọlọ́run ti yàn fún ara rẹ̀. Ǹjẹ́ Ọlọ́run yóò wa lẹ́bi? Bẹ́̀ kọ́! Òun ni ẹni ó dáríjì , ó fi sípò ó dára lọ́dọ̀ rẹ̀. 34 8.34: Ro 8.27.Ta ni ẹni náà yóò wa lẹ́bi? . Kristi Jesu ó , a à kúkú a ti dìde kúrò nínú òkú, ẹni ó ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run, ń bẹ̀bẹ̀ fún wa? 35 Ta ni yóò ha kúrò nínú ìfẹ́ Kristi? Ìpọ́njú ni, tàbí wàhálà tàbí inúnibíni tàbí ìyàn, tàbí ìhòhò, tàbí ewu tàbí idà? 36 8.36: Sm 44.22.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Nítorí rẹ̀ ni a ṣe ń pa gbogbo ọjọ́;

À ń àgùntàn fún pípa."

37 8.37: 1Kọ 15.57. Ṣùgbọ́n nínú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, àwa ju ẹni ó ṣẹ́gun lọ nípasẹ̀ Kristi ẹni ó fẹ́ wa. 38 Nítorí ó mi lójú gbangba , í ṣe ikú tàbí ìyè, í ṣe àwọn angẹli tàbí ̀èṣù, í ṣe ohun ìgbà ìsinsin yìí tàbí ohun ó ń bọ̀, tàbí àwọn agbára, 39 tàbí òkè, tàbí ̀gbun, tàbí ohunkóhun nínú ìṣẹ̀ni yóò le kúrò nínú ìfẹ́ Ọlọ́run ó ń bẹ nínú Kristi Jesu, Olúwa wa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-