Publicidade

Rute 2

Rutu pàdé Boasi

1 Naomi ìbátan kan láti ìdílé Elimeleki ọkọ rẹ̀, aláàánú ọlọ́rọ̀, ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Boasi.

2 Rutu ará Moabu fún Naomi , "Jẹ́ èmi ó lọ inú oko láti ṣá ọkà àwọn olùkórè fi sílẹ̀ ̀dọ̀ ẹnikẹ́ni èmi yóò ojúrere rẹ̀ pàdé."

Naomi sọ fún un , "Máa lọ, ọmọbìnrin mi." 3 Rutu jáde lọ láti ṣá ọkà àwọn olùkórè fi sílẹ̀ lẹ́yìn wọn. Ó jẹ́ inú oko Boasi ó ti ìdílé Elimeleki ni ó lọ láìmọ̀-́n-mọ̀.

4 Nígbà náà ni Boasi láti Bẹtilẹhẹmu ó àwọn olùkórè , "Olúwa pẹ̀yín."

Wọ́n a lóhùn , "Olúwa bùkún fún ."

5 Boasi béèrè lọ́wọ́ olórí àwọn olùkórè , "Ti ta ni ̀dọ́mọbìnrin yẹn?"

6 Ìránṣẹ́ ó jẹ́ olórí àwọn olùkórè náà fèsì , "̀dọ́mọbìnrin ará Moabu ó tẹ̀Naomi láti ilẹ̀ Moabu ni. 7 Ó sọ , ń jọ̀wọ́ jẹ́ òun máa ṣá ọkà lẹ́yìn àwọn olùkórè.Ó ti ń ṣe iṣẹ́ kárakára láti òwúrọ̀ títí di ìsinsin yìí nínú oko àyàfi ìgbà ó lọ láti sinmi fún ìgbà díẹ̀ lábẹ́ ibojì."

8 Nígbà náà ni Boasi sọ fún Rutu , "Gbọ́ ọmọbìnrin mi, ṣe lọ oko mìíràn láti ṣá ọkà, ṣe kúrò ibi. Dúró níbí pẹ̀àwọn ìránṣẹ́bìnrin mi. 9 Wo ibi wọ́n ti ń kórè o máa tẹ̀àwọn obìnrin. Mo ti pàṣẹ fún àwọn ọkùnrin wọ́n ṣe fi ọwọ́ kàn ́. Nígbàkígbà òǹgbẹ ń gbẹ ́, lọ ó mu omi nínú àmù èyí àwọn ọkùnrin ti pọn omi nínú."

10 Rutu wólẹ̀, ó fún Boasi , "Èéṣe èmi fi ojúrere rẹ pàdé báyìí, o kíyèsi mi, èmi àjèjì àti àlejò?"

11 Boasi fèsì , "Èmi ti gbọ́ gbogbo o ti ń ṣe ìyá ọkọ ̀ rẹ láti ìgbà ọkọ rẹ ti àti o ti ṣe fi baba àti ìyá rẹ àti ilẹ̀ rẹ sílẹ̀, o láti gbé láàrín àwọn ènìyàn ìwọ mọ̀ tẹ́lẹ̀ . 12 Olúwa ó san ̀san ohun ìwọ ṣe fún . o gba èrè kíkún láti ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, abẹ́ ìyẹ́ ẹni ìwọ fún ààbò."

13 Rutu fèsì , "èmi ó máa ojúrere láti ̀dọ̀ rẹ síwájú i olúwa mi. Ìwọ ti nínú nípa sísọ ̀rọ̀ rere ìránṣẹ́bìnrin rẹ, ó tilẹ̀ jẹ́ èmi ̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ."

14 Nígbà àkókò oúnjẹ , Boasi sọ fún Rutu , "gba ìwọ̀n àkàrà yìí o fi run wáìnì kíkan."

Òun jókòó pẹ̀àwọn olùkórè, Boasi fún un ọkà yíyan. Òun jẹ́, ó , ó tún ṣẹ́. 15 Nígbà ó dìde láti máa ṣá ọkà, Boasi pàṣẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ , "ó tilẹ̀ ń ṣà láàrín oko ọkà pàápàá, ṣe i lọ́wọ́. 16 ṣe lára àwọn ìtí sílẹ̀ fún láti ṣá, ṣe ba a ."

17 Rutu ń ṣá ọkà títí ó fi di ìrọ̀lẹ́, nígbà ó pa ọkà barle ó ṣà, ó fẹ́ tán, èyí ó ìwọ̀n garawa kan (lita méjìlélógún). 18 Ó gbé e, ó lọ ìlú, ìyá ọkọ rẹ ọkà ó ṣà bi o pọ̀ , Rutu oúnjẹ ó jẹ lẹ́yìn ó ti tan fún ìyá ọkọ rẹ̀.

19 Ìyá ọkọ rẹ̀ bi í léèrè , "Níbo ni ìwọ ti ṣá ọkà lónìí? Àti oko ta ni ìwọ gbé ṣiṣẹ́? Alábùkún fún ni ọkùnrin náà ó bojú ."

Rutu sọ ̀dọ̀ ẹni ó ti ṣiṣẹ́ fún ìyá ọkọ rẹ̀ , "oko ọkùnrin kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Boasi ni mo ti ṣiṣẹ́ lónìí."

20 Naomi fún un , "Olúwa, ó bùkún fún ọkùnrin náà. Ọlọ́run dáwọ́ oore àti àánú ṣíṣe àwọn alààyè àti òkú dúró." Naomi sọ síwájú i , "Ìbátan ó súnmọ́ wa pẹ́kípẹ́ni ọkùnrin náà ń ṣe, ó jẹ́ ̀kan nínú àwọn ó ̀tọ́ láti ra ohun ìní ìdílé padà."

21 Rutu, ará Moabu , "Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ó sọ fún mi , ń máa ṣá ọkà pẹ̀àwọn òṣìṣẹ́ òun, títí wọn yóò fi parí ìkórè.’ "

22 Naomi sọ fún Rutu, ìyàwó ọmọ rẹ̀ , "Ìbá dára ó le àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ ṣiṣẹ́. Nítorí wọ́n le è ́ láàmú o lọ oko ẹlòmíràn."

23 Rutu àwọn ìránṣẹ́bìnrin Boasi ṣiṣẹ́ títí wọ́n fi parí ìkórè ọkà barle àti ti jéró. Ó ń gbé pẹ̀ìyá ọkọ rẹ̀.

Veja também

Rute
Ver todos os capítulos de Rute
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-