Pular para o conteúdo
Publicidade

Rute 4

Boasi gbé Rutu ìyàwó

1 Nígbà náà ni Boasi gòkè lọ ẹnu ibodè ìlú, ó jókòó síbẹ̀. Nígbà ìbátan ó súnmọ́ Elimeleki jùlọ, arákùnrin Boasi ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ ń kọjá, Boasi é , "Máa bọ̀ síbí ìwọ ̀rẹ́ mi, o jókòó." Ó lọ jókòó.

2 Boasi pe mẹ́wàá nínú àwọn àgbàgbà ìlú, ki wọn jókòó, wọn ṣe bẹ́̀, 3 ó sọ fún ìbátan rẹ̀ náà , "Arábìnrin Naomi ó láti ilẹ̀ Moabu fẹ́ ta ilẹ̀, èyí ó ṣe ti arákùnrin Elimeleki wa. 4 ó yẹ n ̀rọ̀ náà etí ìgbọ́ rẹ, o á iwájú gbogbo àwọn ó jókòó ibi yìí. ìwọ yóò á padà á. Ṣùgbọ́n ìwọ á padà, sọ fún mi, èmi ó le è mọ̀. Nítorí ẹlòmíràn ó ̀tọ́ láti á ju ìwọ lọ, èmi ni ẹni ó tún kàn lẹ́yìn rẹ̀."

Ọkùnrin náà sọ , "Èmi yóò á padà."

5 Nígbà náà ni Boasi sọ , "ìwọ ti ra ilẹ̀ náà lọ́wọ́ Naomi àti lọ́wọ́ Rutu ará Moabu, ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ opó ọkùnrin náà, orúkọ ọkùnrin ó náà ba à parẹ́ pẹ̀ohun ìní rẹ̀ àti o le è bímọ orúkọ rẹ̀."

6 Nígbà náà ni ọkùnrin náà dáhùn èyí , "Nípa ti èyí, èmi le è á padà, nítorí , ọmọ rẹ̀, ọkùnrin yóò jẹ́ ajogún àwọn ohun ìní mi pẹ̀. á fún ara rẹ, èmi le ṣe é."

7 4.7: De 25.8-10. ayé ìgbàanì, a le sọ ohun ìràpadà tàbí pàṣípàrọ̀ ohun ìní fi ìdí múlẹ̀ ilẹ̀ Israẹli, ẹnìkan ni láti yọ bàtà rẹ̀ kúrò ẹsẹ̀ rẹ̀ ó fi fún ẹnìkejì, ó jẹ́ òfin fún ẹni ó fẹ́ á. Nípa ṣíṣe èyí, àwọn ará Israẹli fihàn ̀rọ̀ náà ti fìdímúlẹ̀.

8 Nítorí náà, nígbà ọkùnrin náà sọ fún Boasi , "Ìwọ á fúnra rẹ̀," ó yọ bàtà rẹ̀ kúrò ẹsẹ̀ rẹ̀.

9 Nígbà náà ni Boasi fún àwọn àgbàgbà àti àwọn mìíràn ó ibẹ̀ , "Gbogbo yín jẹ́ ẹlẹ́rìí mi òní mo ti ra ohun gbogbo í ṣe ti Elimeleki àti àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin méjèèjì: Maloni àti Kilioni lọ́wọ́ Naomi. 10 àfikún, mo ra Rutu ará Moabu opó Maloni padà láti di aya mi. Èyí yóò orúkọ ọkùnrin òkú náà pẹ̀ohun ìní rẹ̀, ìran rẹ̀ ba à parẹ́ láàrín àwọn ẹbí rẹ̀ àti ìlú rẹ̀. ̀yin ni ẹlẹ́rìí òní."

11 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà àti àwọn ènìyàn ó ibẹ̀ dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àwa ni ẹlẹ́rìí, Olúwa jẹ́ obìnrin ó ń bọ̀ inú ilẹ̀ rẹ dàbí Rakeli àti Lea láti ara àwọn ẹni gbogbo ìdílé Israẹli ti jáde . ìwọ di ọlọ́rọ̀ ìran Efrata àti olókìkí ìlú Bẹtilẹhẹmu. 12 Olúwa fún ọmọ yóò ìdílé rẹ dàbí ti Peresi ọmọkùnrin Tamari fún Juda láti ipasẹ̀ ̀dọ́mọbìnrin yìí."

Ìṣesí Naomi

13 Báyìí ni Boasi ṣe Rutu, ó di aya rẹ̀. Nígbà náà ni ó wọlé tọ aya rẹ̀, Olúwa ó lóyún, ó ọmọ ọkùnrin kan. 14 Àwọn obìnrin fún Naomi , "Ìyìn ni fún Olúwa fi sílẹ̀ òní yìí láìní ìbátan, Olùràpadà. ọmọ náà di olókìkí Israẹli. 15 Yóò tún ayé rẹ ṣe, yóò dáàbò ́ ọjọ́ ogbó rẹ. Nítorí ìyàwó ọmọ rẹ, èyí ó sàn fún ju ọmọkùnrin méje lọ, ó fẹ́ràn rẹ ni ó ọmọ yìí fún."

16 Naomi gbé ọmọ náà orí ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń tọ́rẹ̀. 17 Àwọn obìnrin àdúgbò , "A ọmọkùnrin kan fún Naomi." Wọ́n pe orúkọ rẹ̀ Obedi. Òun ni baba Jese í ṣe baba Dafidi.

Èyí ni ìran Dafidi

18 Èyí ni ìran Peresi:

Peresi ni baba Hesroni,

19 Hesroni ni baba Ramu,

Ramu ni baba Amminadabu

20 Amminadabu ni baba Nahiṣoni,

Nahiṣoni ni baba Salmoni,

21 Salmoni ni baba Boasi,

Boasi ni baba Obedi,

22 Obedi baba Jese,

Jese ni baba Dafidi.

Veja também

Rute
Ver todos os capítulos de Rute