Publicidade

Sofonias 1

1 ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Sefaniah ọmọ Kuṣi, ọmọ Gedaliah, ọmọ Amariah, ọmọ Hesekiah, ìgbà Josiah ọmọ Amoni ọba Juda.

Ìkìlọ̀ fún ìparun ń bọ̀

2 "Èmi yóò gbogbo nǹkan kúrò

lórí ilẹ̀ náà pátápátá,"

ni Olúwa .

3 "Èmi yóò ènìyàn àti ẹranko kúrò;

èmi yóò àwọn ẹyẹ ojú ̀run kúrò, àti ẹja inú Òkun,

àti ohun ìdìgbòlù pẹ̀àwọn ènìyàn búburú;

èmi yóò ènìyàn kúrò lórí ilẹ̀ ayé,"

ni Olúwa .

Ìlòdì Juda

4 "Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Juda

àti sórí gbogbo àwọn ènìyàn ń gbé Jerusalẹmu.

Èmi yóò kúrò níhìn-ín yìí ìyókù àwọn Baali, àti orúkọ àwọn abọ̀rìṣà

pẹ̀àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà,

5 àti àwọn ń foríbalẹ̀ lórí òrùlé,

àwọn ń sin ogun ̀run,

àwọn ń foríbalẹ̀, wọ́n ń fi Olúwa búra,

wọ́n ń fi Moleki búra.

6 Àwọn ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa;

àti àwọn Olúwa, bẹ́̀ ni wọn béèrè rẹ̀."

7 1.7: Hk 2.20; Sk 2.13. dákẹ́ jẹ́́ níwájú Olúwa Olódùmarè,

nítorí ọjọ́ Olúwa dẹ̀dẹ̀.

Olúwa ti pèsè ẹbọ kan sílẹ̀,

ó ti ya àwọn alápèjẹ rẹ̀ mímọ́.

8 "ọjọ́ ẹbọ Olúwa,

Èmi yóò bẹ àwọn olórí ,

àti àwọn ọmọ ọba ọkùnrin,

pẹ̀gbogbo àwọn ó wọ àjèjì aṣọ.

9 ọjọ́ náà, èmi yóò fi ìyà jẹ

gbogbo àwọn ó yẹra láti rìn lórí ìloro ẹnu-ọ̀,

wọ́n kún tẹmpili àwọn ọlọ́run wọn

pẹ̀ìwà ipá àti ̀tàn.

10 "ọjọ́ náà," ni Olúwa ,

"Ohùn ẹkún yóò láti ìhà ibodè ẹja,

híhu láti ìhà kejì àti

ariwo ńlá láti òkè kékeré .

11 hu, ̀yin ń gbé agbègbè ọjà,

gbogbo àwọn oníṣòwò rẹ̀ ni a ó kúrò,

gbogbo àwọn ẹni ó ń ra fàdákà ni a ó parun.

12 àkókò wọ̀n-ọn-nì, èmi yóò Jerusalẹmu kiri pẹ̀fìtílà,

èmi ó fi ìyà jẹ àwọn ìtẹ́lọ́rùn,

wọn dàbí àwọn ènìyàn ó sinmi sínú gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ wọn,

àwọn wọn ń ọkàn wọn , Olúwa yóò ṣe nǹkan kan

ó jẹ́ rere tàbí ó jẹ́ búburú.

13 Nítorí náà, ọrọ̀ wọn yóò di ìkógun,

àti ilé wọn yóò run.

Àwọn yóò kọ́ ilé pẹ̀,

ṣùgbọ́n wọn yóò gbé nínú ilé náà,

wọn yóò gbin ọgbà àjàrà,

ṣùgbọ́n wọn yóò mu ọtí

wáìnì láti inú rẹ̀."

Ọjọ́ ńlá Olúwa

14 "Ọjọ́ ńlá Olúwa dẹ̀dẹ̀,

ó dẹ̀dẹ̀ ó ń yára bọ̀ kánkán.

tẹ́sílẹ̀, ohùn ẹkún àwọn alágbára;

ọjọ́ Olúwa yóò korò púpọ̀,

15 ọjọ́ náà yóò jẹ́ ọjọ́ ìbínú,

ọjọ́ ìrora àti ìpọ́njú,

ọjọ́ òfò àti idà ọjọ́ ìdahoro

ọjọ́ òkùnkùn àti ìtẹ̀ba,

ọjọ́ kurukuru àti òkùnkùn biribiri,

16 ọjọ́ ìpè àti ìpè ogun

àwọn ìlú olódi

àti àwọn ilé ìṣọ́ gíga.

17 "Èmi yóò ìpọ́njú sórí ènìyàn,

wọn yóò máa rìn gẹ́gẹ́ afọ́,

nítorí àwọn ti dẹ́ṣẹ̀ Olúwa.

̀jẹ̀ wọn ni a ó jáde eruku

àti ẹran-ara wọn ìgbẹ́.

18 Bẹ́̀ ni fàdákà tàbí wúrà wọn

yóò le gbà wọ́n

ọjọ́ ìbínú Olúwa."

Ṣùgbọ́n gbogbo ayé ni a ó fi iná

ìjowú rẹ̀ parun,

nítorí òun yóò fi ìyára fi òpin

gbogbo àwọn ń gbé ilẹ̀ ayé.

Veja também

Sofonias
Ver todos os capítulos de Sofonias
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-