Publicidade

Sofonias 3

Ọjọ́ iwájú Jerusalẹmu

1 Ègbé ni fún ìlú aninilára,

ọlọ̀tẹ̀ àti aláìmọ́.

2 Òun gbọ́rọ̀ ẹnikẹ́ni,

òun gba ìtọ́ni,

òun gbẹ́kẹ̀Olúwa,

bẹ́̀ ni òun súnmọ́ ̀dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀.

3 Àwọn olórí rẹ̀ jẹ́ kìnnìún ń ramúramù,

àwọn onídàájọ́ rẹ̀, ìkookò àṣálẹ́ ni wọn,

wọn fi nǹkan kan kalẹ̀ fún òwúrọ̀.

4 Àwọn wòlíì rẹ̀ gbéraga,

wọ́n jẹ́ alárékérekè ènìyàn.

Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti ba ibi mímọ́ jẹ́,

wọ́n òfin.

5 Olúwa ni àárín rẹ̀ jẹ́ olódodo;

yóò ṣe ohun tọ̀.

Àràárọ̀ ni ó máa ń ìdájọ́ rẹ̀ ìmọ́lẹ̀,

í kùnà gbogbo ọjọ́ tuntun,

síbẹ̀ àwọn aláìṣòótọ́ mọ ìtìjú.

6 "Èmi ti àwọn orílẹ̀-èdè kúrò,

ilé gíga wọn ti bàjẹ́.

Mo ti fi ìgboro wọn sílẹ̀ òfo

bẹ́̀ ẹnìkankan kọjá níbẹ̀.

Ìlú wọn parun bẹ́̀

ẹnìkan yóò ṣẹ́,

ẹnìkan rárá.

7 Èmi fún ìlú náà ,

Nítòótọ́, ìwọ yóò bẹ̀mi,

ìwọ yóò gba ìtọ́ni!

Bẹ́̀ ni, a yóò ibùgbé rẹ̀ kúrò

ó ti ń jẹ wọ́n .

Ṣùgbọ́n síbẹ̀ wọ́n tún ìtara

láti ṣe ìbàjẹ́.

8 Nítorí náà dúró ," ni Olúwa ,

"títí di ọjọ́ náà èmi yóò fi jẹ́rìí yin.

Nítorí ìpinnu mi ni láti orílẹ̀-èdè jọ

èmi ó ilẹ̀ ọba jọ

àti láti da ìbínú mi jáde sórí wọn,

àní gbogbo ìbínú gbígbóná mi.

Nítorí gbogbo ayé

ni a ó fi iná owú mi jẹ run.

Ìràpadà àwọn ènìyàn tókù

9 "Nígbà náà ni èmi yóò èdè àwọn ènìyàn padà èdè mímọ́,

nítorí gbogbo wọn a máa pe orúkọ Olúwa,

láti fi ọkàn kan sìn ín.

10 Láti òkè odò Etiopia,

àwọn olùjọsìn mi, àwọn ènìyàn mi ó ti fọ́nká,

yóò ọrẹ fún mi.

11 ọjọ́ náà ni a yóò dójútì

nítorí gbogbo iṣẹ́ ibi ni ó ti ṣẹ̀ mi,

nígbà náà ni èmi yóò mu

kúrò nínú ìlú yìí, àwọn ń yọ̀ nínú ìgbéraga wọn.

Ìwọ yóò gbéraga mọ́

òkè mímọ́ mi.

12 Ṣùgbọ́n Èmi yóò fi àwọn ọlọ́kàn tútù

àti onírẹ̀lẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀ni àárín rẹ̀,

wọn yóò gbẹ́kẹ̀orúkọ Olúwa.

13 Àwọn ìyókù Israẹli yóò hùwà ibi,

wọn yóò sọ̀rọ̀ èké.

Bẹ́̀ ni a yóò

ahọ́n àrékérekè ẹnu wọn.

Àwọn yóò jẹun, wọn yóò dùbúlẹ̀,

bẹ́̀ ni ẹnikẹ́ni yóò dẹ́rùbà wọ́n."

14 Kọrin, ìwọ ọmọbìnrin Sioni,

kígbe sókè, ìwọ Israẹli!

Fi gbogbo ọkàn yọ̀, inú rẹ ó dùn,

ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu.

15 Olúwa ti ìdájọ́ rẹ wọ̀n-ọn-nì kúrò,

ó ti ti àwọn ̀rẹ padà sẹ́yìn.

Olúwa, ọba Israẹli pẹ̀rẹ;

ìwọ yóò bẹ̀ibi kan mọ́.

16 ọjọ́ náà, wọn yóò sọ fún Jerusalẹmu ,

"ṣe bẹ̀Sioni;

ṣe jẹ́ ọwọ́ rẹ ó dẹ̀.

17 Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀rẹ,

Ó agbára láti gbà .

Yóò yọ̀ ni orí rẹ fún ayọ̀;

Yóò tún ṣe nínú ìfẹ́ rẹ̀,

Yóò fi orin yọ̀ orí rẹ."

18 "Èmi ó àwọn ó ń banújẹ́ fún àjọ̀dún a yàn jọ,

àwọn ó jẹ́ tirẹ̀;

àwọn ̀gàn rẹ̀ jásí ̀.

19 àkókò náà

ni èmi yóò dojúkọ àwọn

ń ni yín lára,

èmi yóò gba àtiro ,

èmi yóò ṣa àwọn ó ti fọ́nká jọ,

èmi yóò fi ìyìn àti ọlá fún wọn

gbogbo ilẹ̀ a ti dójútì wọ́n.

20 àkókò náà ni èmi yóò ṣà yín jọ;

nígbà náà ni èmi yóò un yín padà sílé.

Èmi yóò fi ọlá àti ìyìn fún un yín

láàrín gbogbo ènìyàn àgbáyé,

nígbà èmi yóò ìgbèkùn yín

padà bọ sípò ojú ara yín,"

ni Olúwa .

Veja também

Publicidade
Sofonias
Ver todos os capítulos de Sofonias
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-