7 ensinamentos de Jesus sobre relacionamento na Bíblia
Os ensinamentos de Jesus sobre relacionamento vão além de conselhos práticos, eles são lições profundas sobre amor, perdão, humildade e cuidado com o próximo. Seja no contexto familiar, de amizade ou comunitário, suas palavras nos mostram como viver em harmonia com os outros.
A seguir, abordamos sete momentos em que Jesus falou sobre relacionamentos na Bíblia:
1. Amar o próximo como a si mesmo
Jesu dáhùn pé, " ‘Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ẹ̀mí rẹ àti gbogbo inú rẹ.’ Èyí ni òfin àkọ́kọ́ àti èyí tí ó tóbi jùlọ. Èkejì tí ó tún dàbí rẹ̀ ní pé, ‘Fẹ́ràn ọmọnìkejì rẹ gẹ́gẹ́ bí ara rẹ.’
Esse ensinamento resume toda a Lei e os Profetas, destacando que o amor ao próximo é fundamental em qualquer relacionamento.
2. Perdoar de coração
Òwe aláìláàánú ọmọ ọ̀dọ̀
Nígbà náà ni Peteru wá sọ́dọ̀ Jesu, ó béèrè pé, "Olúwa, nígbà mélòó ni arákùnrin mi yóò ṣẹ̀ mi, tí èmi yóò sì dáríjì í? Tàbí ní ìgbà méje ni?"
Jesu dáhùn pé, "Mo wí fún ọ, kì í ṣe ìgbà méje, ṣùgbọ́n ní ìgbà àádọ́rin méje.
Jesus enfatiza a necessidade de perdoar ilimitadamente, promovendo a reconciliação e a paz.
3. Servir uns aos outros
Ṣùgbọ́n èyí yàtọ̀ láàrín yín. Dípò bẹ́ẹ̀, ẹni tí ó bá ń fẹ́ ṣe olórí láàrín yín, ní láti ṣe bí ìránṣẹ́ fún yín ni, àti ẹni tí ó bá fẹ́ ṣe olórí nínú yín, ẹ jẹ́ kí ó máa ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ yin.
Aqui, Jesus ensina que a verdadeira liderança e grandeza estão em servir os outros com humildade.
4. Amar até os inimigos
Ṣùgbọ́n èmi wí fún yín pé, ẹ fẹ́ràn àwọn ọ̀tá yín kí ẹ sì gbàdúrà fún àwọn tí ń ṣe inúnibíni sí yín.
Esse mandamento radical desafia nossos limites de amor, mostrando que relacionamentos saudáveis envolvem superar rancores.
5. Evitar julgamentos precipitados
Ṣíṣe ìdájọ́ ẹnìkejì
"Ẹ má ṣe dá ni lẹ́jọ́, kí a má bà dá yín lẹ́jọ́. Nítorí irú ìdájọ́ tí ẹ̀yin bá ṣe, òun ni a ó sì ṣe fún yín; irú òsùwọ̀n tí ẹ̀yin bá fi wọ́n, òun ni a ó sì fi wọ́n fún yín.
Jesus nos lembra de praticar a empatia e a compreensão antes de condenar os outros.
6. Construir relacionamentos com base no amor
Èyí ni òfin mi, pé kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn ara yín, gẹ́gẹ́ bí mo ti fẹ́ràn yín.
Esse mandamento reforça que o padrão de amor para os relacionamentos deve ser o amor incondicional de Jesus.
7. Reconciliar-se antes de adorar a Deus
"Nítorí náà, nígbà tí ìwọ bá ń mú ẹ̀bùn rẹ wá síwájú pẹpẹ, bí ìwọ bá sì rántí níbẹ̀ pé arákùnrin rẹ̀ ni ohùn kan nínú sí ọ. Fi ẹ̀bùn rẹ sílẹ̀ níwájú pẹpẹ. Ìwọ kọ́kọ́ lọ ṣe ìlàjà láàrín ìwọ àti arákùnrin rẹ̀ na. Lẹ́yìn náà, wá kí ó sì fi ẹ̀bùn rẹ sílẹ̀.
Jesus ensina que a reconciliação é um passo essencial para nossa comunhão com Deus.
Esses ensinamentos de Jesus nos convidam a transformar nossos relacionamentos em reflexos do amor divino, construindo uma vida baseada na paz, no perdão e na empatia. Aproveite e convide mais pessoas a lerem este artigo, compartilhe a Palavra de Deus.