Publicidade

Mateus 20

Òwe àwọn òṣìṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà

1 20.1: Mt 21.28,33. "Nítorí ìjọba ̀run dàbí ọkùnrin ó jẹ́ baálé kan, ó jíjáde lọ kùtùkùtù òwúrọ̀, ó gba àwọn alágbàṣe sínú ọgbà àjàrà rẹ̀. 2 Òun pinnu láti san dínárì kan fún iṣẹ́ òòjọ́ kan. Lẹ́yìn èyí ó rán wọn lọ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀.

3 "wákàtí kẹta ọjọ́ ó ti ń kọjá níwájú ilé ìgbanisíṣẹ́, ó díẹ̀ nínú àwọn aláìríṣẹ́ wọ́n dúró ọjà. 4 Ó fún wọn , ̀yin pàápàá, lọ ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà mi, ó di òpin ọjọ́, èmi yóò san iye ti ó yẹ fún yín. 5 Wọ́n lọ.

"Ó tún jáde lọ́sàn án nǹkan wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsànán, ó túnṣe bákan náà. 6 Lọ́jọ́ kan náà wákàtí kọkànlá ọjọ́, ó tún jáde àárín ìlú, ó àwọn aláìríṣẹ́ mìíràn wọ́n dúró. Ó bi wọ́n , Èéṣe ̀yin í ṣiṣẹ́ gbogbo ọjọ́?’

7 "Wọ́n dáhùn , Nítorí ẹni yóò fún wa iṣẹ́ ṣe.

"Ó tún sọ fún wọn , ̀yin náà jáde lọ ṣiṣẹ́ pẹ̀nínú ọgbà àjàrà mi.

8 20.8: Le 19.13; De 24.15. "Nígbà ó di àṣálẹ́, ẹni ni ọgbà àjàrà sọ fún aṣojú rẹ̀ , Pe àwọn òṣìṣẹ́ náà, ó san owó iṣẹ́ wọn fún wọn, bẹ̀rẹ̀ láti ẹni ìkẹyìn lọ ti ìṣáájú.

9 "Nígbà àwọn ti a wákàtí kọkànlá ọjọ́ , ẹnìkọ̀̀kan gba owó dínárì kan. 10 Nígbà àwọn a gbà ṣiṣẹ́ lákọ̀́kọ́ fẹ́ gba owó tiwọn, èrò wọn ni àwọn yóò gba bẹ́̀ lọ, ṣùgbọ́n ẹnìkọ̀̀kan wọn gba owó dínárì kan. 11 wọ́n ti ń gbà á, wọ́n ń kùn onílẹ̀ náà, 12 , Wákàtí kan péré ni àwọn a gbà kẹ́yìn fi ṣiṣẹ́, ìwọ san iye kan náà fún wọn àti àwa náà ti a fi gbogbo ọjọ́ ṣiṣẹ́ nínú oòrùn gangan.

13 20.13: Mt 22.12; 26.50. "Ṣùgbọ́n ó ̀kan nínú wọn lóhùn , ̀rẹ́, aburú nínú nǹkan èmi ṣe yín. í ha ṣe ̀yin gbà láti ṣiṣẹ́ fún owó dínárì kan. 14 Ó , gba èyí í ṣé tìrẹ, ki ó máa lọ. Èmi fẹ́ láti fún ẹni ìkẹyìn gẹ́gẹ́ mo ti fi fún . 15 Àbí ó lòdì òfin èmi fún ẹnikẹ́ni owó mi mo yàn láti ṣe bẹ́̀? ni ìdí ìwọ láti bínú nítorí èmi ṣe ohun rere?

16 20.16: Lk 13.30; Mt 19.30; Mk 10.31. "Bẹ́̀ ni àwọn ẹni ìkẹyìn yóò di ẹni ìṣáájú, ẹni ìṣáájú yóò di ẹni ìkẹyìn."

Jesu tún sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀

17 20.17-19: Mk 10.32-34; Lk 18.31-34; Mt 16.21; 17.12,22-23; 26.2. Jesu ti ń gòkè lọ Jerusalẹmu, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá apá kan ó , 18 "ó, àwa ń gòkè lọ Jerusalẹmu. Ó sọ fún wọn , a ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin lọ́wọ́, wọn yóò mi lẹ́bi ikú. 19 Wọn yóò á àwọn kèfèrí lọ́wọ́ láti fi ṣe ẹlẹ́àti láti náà án, àti láti kàn mi mọ́ àgbélébùú, ọjọ́ kẹta, yóò dìde."

̀bẹ̀ ìyá

20 20.20-24: Mk 10.35-41. 20.20: Mt 8.2; 9.18; 15.25; 18.26; Jh 9.38. Nígbà náà ni ìyá àwọn ọmọ Sebede àwọn ọmọ rẹ̀ sọ́dọ̀ Jesu, ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, o béèrè fún ojúrere rẹ̀.

21 20.21: Mt 19.28. Jesu béèrè , "ni ìwọ ń fẹ́?"

Ó dáhùn , "Jẹ́ àwọn ọmọ mi méjèèjì jókòó apá ̀tún àti apá òsì lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ?"

22 20.22: Mt 26.39; Jh 18.11. Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn ó , "̀yin mọ ohun ̀yin ń béèrè, ̀yin ha le mu nínú ago èmi ó mu?"

Wọ́n dáhùn , "Àwa mu ún."

23 20.23: Ap 12.2; Ro 1.9; Mt 13.11. Jesu fún wọn , "Dájúdájú, ̀yin yóò mu nínú ago mi, ṣùgbọ́n èmi àṣẹ láti sọ irú ènìyàn yóò jókòó apá ̀tún tàbí apá òsì. Baba mi ti pèsè ààyè wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀ fún kìkì àwọn ó yàn."

24 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá ìyókù gbọ́ èyí, wọ́n bínú àwọn arákùnrin méjì yìí. 25 20.25-28: Mk 10.42-45; Lk 22.25-27.Ṣùgbọ́n Jesu wọ́n papọ̀, ó , "Dájúdájú, ̀yin mọ̀ àwọn ọba aláìkọlà a máa lo agbára lórí wọn, àwọn ẹni ńlá láàrín wọn a máa fi ọlá tẹrí àwọn ó lábẹ́ wọn ba. 26 Ṣùgbọ́n èyí yàtọ̀ láàrín yín. Dípò bẹ́̀, ẹni ó ń fẹ́ ṣe olórí láàrín yín, láti ṣe ìránṣẹ́ fún yín ni, 27 àti ẹni ó fẹ́ ṣe olórí nínú yín, jẹ́ ó máa ṣe ọmọ ̀dọ̀ yin. 28 Gẹ́gẹ́ Ọmọ Ènìyàn ṣe ayé, ṣe ìránṣẹ́ fún un, ṣùgbọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fún yín, àti láti fi ̀rẹ ṣe ìràpadà ̀pọ̀ ènìyàn."

Afọ́méjì ríran

29 20.29-34: Mk 10.46-52; Lk 18.35-43; Mt 9.27-31. Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti ń fi ìlú Jeriko sílẹ̀, ̀pọ̀ ènìyàn wọ́ tẹ̀e lẹ́yìn. 30 Àwọn ọkùnrin afọ́méjì jókòó lẹ́bàá ̀, nígbà wọ́n gbọ́ Jesu ń kọjá lọ, wọ́n bẹ̀rẹ̀ í kígbe , "Olúwa, Ọmọ Dafidi, ṣàánú fún wa!"

31 Àwọn ènìyàn wọn wọn dákẹ́, ṣùgbọ́n wọ́n kígbe sókè i. "Olúwa, ọmọ Dafidi, ṣàánú fún wa!"

32 Jesu dúró lójú ̀, ó wọ́n, Ó béèrè , "ni ̀yin fẹ́ èmi ṣe fún yín?"

33 Wọ́n dáhùn , "Olúwa, àwa fẹ́ a ríran."

34 Àánú wọn ṣe Jesu, ó fi ọwọ́ kan ojú wọn. Lójúkan náà, wọ́n ríran, wọ́n ń tọ̀ ́ lẹ́yìn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-