Publicidade

Esperar no Senhor

Por Bíblia Online

Esperar no Senhor é ato de fé e confiança. A Bíblia promete que os que esperam em Deus renovam as forças, recebem direção e experimentam a fidelidade divina no tempo certo.

Renovar as forças

Os que esperam no Senhor renovam as forças. Sobem como águias, correm e não se cansam, caminham e não se fatigam.

ṣùgbọ́n àwọn ó gbẹ́kẹ̀Olúwa

yóò sọ agbára wọn di ̀tun.

Wọn yóò fìyẹ́ lókè idì;

wọn yóò sáré àárẹ̀ wọn,

wọn yóò rìn òòyì kọ́ wọn.

Síbẹ̀síbẹ̀ Olúwa fẹ́ síjú àánú ́;

ó dìde láti ṣàánú fún .

Nítorí Olúwa jẹ́ Ọlọ́run ìdájọ́.

Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn ó dúró é!

Dúró de Olúwa;

ó jẹ alágbára, o ọkàn le

àní dúró de Olúwa.

Èmi ìgbàgbọ́ ,

èmi yóò ìre Olúwa

ilẹ̀ alààyè.

Dúró de Olúwa;

ó jẹ alágbára, o ọkàn le

àní dúró de Olúwa.

Olúwa ni ìmọ́lẹ̀ mi àti ìgbàlà mi;

ta ni èmi yóò bẹ̀?

Olúwa ni ibi ìsádi ̀mi,

̀ta ni yóò ?

Nígbà àwọn ènìyàn búburú kọjú ìjà mi

láti jẹ ẹran-ara mi,

àní àwọn ̀mi àti àwọn abínúkú mi,

wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò ṣubú.

ọmọ-ogun tilẹ̀ mi wọ́n dìde mi,

ọkàn mi yóò bẹ̀;

ogun tilẹ̀ dìde mi,

nínú èyí ni ọkàn mi yóò le.

Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa,

òhun ni èmi yóò máa kiri:

èmi ó le ilé Olúwa

ọjọ́ ayé mi gbogbo,

èmi: ó le kíyèsi ẹwà Olúwa,

èmi ó máa tẹmpili rẹ̀.

Nítorí ìgbà ìpọ́njú

òun yóò pa mọ́ nínú àgọ́ rẹ̀;

níbi ìkọ̀kọ̀ àgọ́ rẹ̀ ni òun yóò pa mọ́;

yóò gbé mi sókè lórí àpáta.

ìsinsin yìí, a ti gbé orí mi sókè

ga ju ti àwọn ̀mi lọ ó ;

èmi yóò ẹbọ nínú àgọ́ rẹ, ẹbọ ariwo àti ti ayọ̀;

èmi yóò kọrin àní orin dídùn Olúwa.

Gbọ́ ohùn mi nígbà ̀à ń , Olúwa,

ṣe àánú fún mi o mi lóhùn,

Ọkàn mi , "ojú u rẹ̀!"

Ojú rẹ, Olúwa, ni ti èmí ń .

ṣe fi ojú rẹ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi,

ṣe fi ìbínú ìránṣẹ́ rẹ ;

ìwọ o ti jẹ́ olùrànlọ́wọ́ mi,

ṣe fi sílẹ̀, ṣe kọ̀ ,

háà! Ọlọ́run ìgbàlà mi.

ìyá àti baba kọ̀ sílẹ̀,

Olúwa yóò tẹ́wọ́ gbà .

Kọ́ mi ̀rẹ, Olúwa,

o sìn mi lọ ̀ó tẹ́

nítorí àwọn ̀mi.

ṣe fi ìfẹ́ àwọn ̀mi lọ́wọ́,

nítorí àwọn ẹlẹ́rìí èké ti dìde mi,

wọ́n ìmí ìkà.

Èmi ìgbàgbọ́ ,

èmi yóò ìre Olúwa

ilẹ̀ alààyè.

Dúró de Olúwa;

ó jẹ alágbára, o ọkàn le

àní dúró de Olúwa.

Espera paciente

Esperei com paciência no Senhor e Ele se inclinou para mim. Confie nele e descanse — Ele agirá no tempo certo.

Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa;

ó dẹtí mi, ó gbọ́ ẹkún mi.

Ó yọ gòkè

láti inú ihò ìparun,

láti inú ẹrẹ̀ pọ̀tọ̀pọ́tọ̀,

ó fi ẹsẹ̀ mi orí àpáta,

ó jẹ́ ìgbésẹ̀ mi láìfòyà.

Ó fi orin tuntun mi lẹ́nu,

àní orin ìyìn Ọlọ́run wa.

̀pọ̀ yóò i wọn yóò bẹ̀,

wọn yóò gbẹ́kẹ̀Olúwa.

Ayọ̀ ni fún àwọn wọ̀n-ọn-nì

ó fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀wọn

wọn yípadà agbéraga,

tàbí àwọn ó yapa

lọ ̀dọ̀ ọlọ́run mìíràn.

Olúwa Ọlọ́run mi,

̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn iṣẹ́ ìyanu ìwọ ti ṣe.

Àwọn ohun ìwọ ti ṣètò sílẹ̀ fún wa;

ni ẹnikẹ́ni le wọ́n fún lẹ́sẹẹsẹ,

èmi yóò sọ̀rọ̀ wọn,

wọ́n ju ohun

ènìyàn le è lọ.

Ẹbọ àti ẹran ẹbọ ni ìwọ fẹ́,

ìwọ ti ṣí mi etí.

Ọrẹ ẹbọ sísun àti ẹbọ ̀ṣẹ̀

ni ìwọ béèrè.

Nígbà náà ni mo ,

"Èmi nìyí;

nínú ìwé kíká ni

a kọ nípa tèmi .

Mo inú dídùn

láti ṣe ìfẹ́ ̀ rẹ,

ìwọ Ọlọ́run mi,

òfin rẹ̀ ń bẹ àyà mi."

Èmi ti sọ ìròyìn ayọ̀ ti ìgbàlà

láàrín àwùjọ ńlá;

ó,

èmi pa ètè mi mọ́,

gẹ́gẹ́ ìwọ ti mọ̀,

ìwọ Olúwa.

Èmi fi ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà sin àyà mi;

èmí ti sọ̀rọ̀ nípa òtítọ́ àti ìgbàlà rẹ.

Èmi pa ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀ mọ́

kúrò láàrín àwọn ìjọ ńlá.

Ìwọ ṣe, fa àánú rẹ ó rọ́sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa;

jẹ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ àti òtítọ́ rẹ

ó máa pa mi mọ́ títí ayérayé.

Nítorí àìníye ibi

ni ó mi káàkiri,

̀ṣẹ̀ mi mọ́ mi,

títí èmi fi ríran mọ́;

wọ́n pọ̀ ju irun orí mi lọ,

àti àyà ti kùnà.

Jẹ́ ó ́,

ìwọ Olúwa,

láti gbà ;

Olúwa,

yára láti ràn lọ́wọ́.

Gbogbo àwọn wọ̀n-ọn-nì ni ojú ó

wọn ó dààmú;

àwọn ń ọkàn mi láti parun

jẹ́ a wọn padà sẹ́yìn a dójútì wọ́n,

àwọn ń ìpalára mi.

Ọkàn wa dúró de Olúwa;

òun ni ìrànlọ́wọ́ wa àti asà wa.

Ọkàn wa yọ̀ nínú rẹ̀,

nítorí , àwa gbẹ́kẹ̀orúkọ rẹ mímọ́.

àánú rẹ, Olúwa, ó lára wa,

àní gẹ́gẹ́ àwa ti ń ṣe ìrètí nínú rẹ.

Èmi dúró de Olúwa, ọkàn mi dúró,

àti nínú ̀rọ̀ rẹ ni èmi ń ṣe ìrètí.

Ọkàn mi dúró de Olúwa,

ju àwọn ń ṣọ́òwúrọ̀ lọ,

àní ju àwọn ń ṣọ́òwúrọ̀ lọ.

Nínú Ọlọ́run nìkan ni ìsinmi , ìwọ Ọlọ́run mi.

Ìrètí mi láti ̀dọ̀ rẹ.

Dúró de Olúwa,

o máa pa ̀rẹ̀ mọ́.

Yóò gbé lékè láti jogún ilẹ̀ náà;

nígbà a àwọn ènìyàn búburú kúrò ìwọ yóò ri.

Confiança e perseverança

Confie no Senhor de todo o coração. Sede pacientes na tribulação — o Senhor é fiel e cumprirá todas as suas promessas.

Gbẹ́kẹ̀Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ

ṣe sinmi òye ara à rẹ.

Mọ̀ ́n gbogbo ̀rẹ

òun yóò máa tọ́ ipa ̀rẹ.

í ṣe bẹ́̀ nìkan, ṣùgbọ́n àwa tún ń ṣògo nínú ìjìyà pẹ̀, a ti mọ̀ ìjìyà ń ṣiṣẹ́ sùúrù; àti sùúrù ń ṣiṣẹ́ ìwà rere; àti ìwà rere ń ṣiṣẹ́ ìrètí.

a fi ipa gbogbo sọ yín di alágbára gẹ́gẹ́ agbára rẹ̀ àti ògo rẹ̀, ó ṣe é ṣe fún un yín láti máa tẹ̀síwájú nínú sùúrù àti ìpamọ́ra pẹ̀ayọ̀.

Sùúrù nínú ìjìyà

Nítorí náà ará, sùúrù títí di ìpadà Olúwa. Kíyèsi i, àgbẹ̀ a máa retí èso iyebíye ti ilẹ̀, a sùúrù é, títí di ìgbà àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò. ̀yin pẹ̀, sùúrù; fi ọkàn yín balẹ̀, nítorí ìpadà Olúwa dẹ̀dẹ̀.

à ó, àwa a máa ka àwọn ó fi ara ìyà ẹni ìbùkún. ̀yin ti gbọ́ ti sùúrù Jobu, ̀yin ìgbẹ̀yìn Olúwa ṣe; Olúwa kún fún ìyọ́, ó àánú.

Níwọ́n ̀yin ti wẹ ọkàn yin mọ́ nípa ìgbọ́ràn yín òtítọ́ ìfẹ́ ará ti ̀tàn, fẹ́ ọmọnìkejì yín gidigidi láti ọkàn . a ti tún yín , í ṣe láti inú ìdíbàjẹ́ , ṣe èyí ti í díbàjẹ́ nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run ń bẹ láààyè ó dúró. Nítorí ,

"Gbogbo ènìyàn dàbí koríko,

àti gbogbo ògo rẹ̀ bi ìtànná koríko.

Koríko á máa gbẹ ìtànná a máa rẹ̀ dànù,

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Olúwa dúró títí láé."

̀rọ̀ náà yìí ni ìyìnrere a wàásù fún yín.

Olúwa fi ìlérí rẹ̀ jáfara, àwọn ẹlòmíràn ti ka ìjáfara ; ṣùgbọ́n ó ń sùúrù fún yín nítorí fẹ́ ẹnikẹ́ni ṣègbé, ṣe gbogbo ènìyàn ìrònúpìwàdà.

Òwe àwọn wúńdíá mẹ́wàá

"Nígbà náà ni ó fi ìjọba ̀run àwọn wúńdíá mẹ́wàá. Ti wọ́n gbé fìtílà wọn láti lọ pàdé ọkọ ìyàwó. Márùn-ún nínú wọn jẹ́ ọlọ́gbọ́n, márùn-ún nínú wọn ni wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n. Àwọn wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n gbé fìtílà wọn ṣùgbọ́n wọn epo kankan lọ́wọ́. Àwọn ọlọ́gbọ́n epo sínú kólòbó lọ́wọ́ pẹ̀fìtílà wọn. Nígbà ọkọ ìyàwó pẹ́, gbogbo wọn tòògbé wọn sùn.

"Nígbà ó di ̀gànjọ́, igbe ta sókè, ó, ọkọ ìyàwó ń bọ̀, jáde sóde láti pàdé rẹ̀.’

"Nígbà náà ni àwọn wúńdíá tají, wọ́n tún fìtílà wọn ṣe. Àwọn aláìgbọ́n márùn-ún epo rárá bẹ àwọn ọlọ́gbọ́n wọn fún àwọn nínú èyí wọ́n nítorí fìtílà wọn ń lọ.

"Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n márùn-ún dáhùn , bẹ́̀ kọ́; ó ba à ṣe aláìtó fún àwa àti ̀yin, kúkú tọ àwọn ń á lọ, fún ara yín.

"àsìkò wọ́n lọ ra epo tiwọn, ni ọkọ ìyàwó . Àwọn wúńdíá ó múra tán a wọlé ibi àsè ìgbéyàwó, lẹ́yìn náà, a ti ìlẹ̀kùn.

"ìkẹyìn ni àwọn wúńdíá márùn-ún ìyókù , wọ́n ń , Olúwa, Olúwa, ṣílẹ̀kùn fún wa.

"Ṣùgbọ́n ọkọ ìyàwó dáhùn , Lóòótọ́ ni mo fún yín èmi mọ̀ yín .

"Nítorí náà, máa ṣọ́. Nítorí ̀yin mọ ọjọ́ tàbí wákàtí Ọmọ Ènìyàn yóò .

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-