Publicidade

Salmos 130

Orin fún ìgòkè.

1 Láti inú ibú ni

èmi ń é ́ Olúwa

2 Olúwa, gbóhùn mi,

jẹ́ etí rẹ o tẹ́ sílẹ̀ ohùn ̀bẹ̀ mi.

3 130.3: Sm 143.2; Ro 3.20; Ga 2.16. Olúwa, ìbá ṣe ìwọ máa sàmì ̀ṣẹ̀,

Olúwa, ni ìbá dúró.

4 Nítorí ìdáríjì lọ́dọ̀ rẹ,

a máa bẹ̀rẹ.

5 Èmi dúró de Olúwa, ọkàn mi dúró,

àti nínú ̀rọ̀ rẹ ni èmi ń ṣe ìrètí.

6 Ọkàn mi dúró de Olúwa,

ju àwọn ń ṣọ́òwúrọ̀ lọ,

àní ju àwọn ń ṣọ́òwúrọ̀ lọ.

7 Israẹli, ìwọ ìrètí ti Olúwa:

nítorí lọ́dọ̀ Olúwa ni àánú ,

àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni ̀pọ̀lọpọ̀ ìdáǹdè .

8 Òun ó Israẹli ìdè

kúrò nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gbogbo.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-