Publicidade

1 Coríntios 11

1 máa tẹ̀àpẹẹrẹ mi, gẹ́gẹ́ èmi náà ti ń tẹ̀àpẹẹrẹ Kristi.

Ìbámu nínú ìsìn

2 Èmí yìn yín fún rírántí mi nínú ohun gbogbo àti fún dídi gbogbo ̀kọ́ mo kọ́ yín ṣinṣin gẹ́gẹ́ mo ṣe fi lélẹ̀ fún un yín. 3 Ṣùgbọ́n mo fẹ́ ̀yin mọ̀ , Kristi ni orí olúkúlùkù ọkùnrin, orí obìnrin ni ọkọ rẹ̀ àti orí Kristi Ọlọ́run. 4 Gbogbo ọkùnrin borí rẹ̀ nígbà ń gbàdúrà tàbí sọtẹ́lẹ̀ bọ̀wọ̀ fún orí rẹ̀. 5 Bẹ́̀ náà ni obìnrin ó ń gbàdúrà tàbí ó ń sọtẹ́lẹ̀ láìbo orí rẹ̀, bu ọlá fún orí ara rẹ̀ nítorí ̀kan náà ni pẹ̀ẹni ó fárí. 6 Ṣùgbọ́n obìnrin kọ̀ láti bo orí rẹ̀, jẹ́ ó irun rẹ̀. ó jẹ́ nǹkan ìtìjú fún un láti irun orí rẹ́, nígbà náà ó fi gèlè bo orí rẹ̀.

7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin láti fi nǹkan bo orí rẹ́ nígbà ó ń sìn, nítorí àwòrán àti ògo Ọlọ́run ni òun í ṣe, ṣùgbọ́n ògo ọkùnrin ni obìnrin í ṣe. 8 Ọkùnrin ti inú obìnrin , ṣùgbọ́n a yọ obìnrin jáde lára ọkùnrin, 9 bẹ́̀ ni a ọkùnrin fún àǹfààní obìnrin ṣùgbọ́n a da obìnrin fún ọkùnrin. 10 Nítorí ìdí èyí àti nítorí àwọn angẹli, ni obìnrin ṣe gbọdọ̀ àmì àṣẹ rẹ̀ orí rẹ̀. 11 rántí , nínú ètò Ọlọ́run obìnrin láìsí ọkùnrin, bẹ́̀ ni ọkùnrin láàsí obìnrin. 12 Lóòtítọ́ láti ara ọkùnrin ni a ti yọ obìnrin jáde bẹ́̀ ni ọkùnrin tipasẹ̀ obìnrin wa. Ṣùgbọ́n láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ohun gbogbo ti .

13 ni ̀yìn fúnra yín lórí ̀rọ̀ yìí? Ǹjẹ́ ó tọ̀fún obìnrin láti máa gbàdúrà Ọlọ́run gbangba láìbo orí rẹ̀ ? 14 Ǹjẹ́ ìwà abínibí yín ha kọ́ yín , ọkùnrin irun gígùn, àbùkù ni ó jẹ́ fún un. 15 Ṣùgbọ́n obìnrin irun gígùn, ògo ni ó jẹ́ fún un nítorí irun gígùn a fi fún un jẹ́ ìbòrí fún un. 16 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni fẹ́ jiyàn lórí ̀rọ̀ yìí, ohun kan mo sọ gbogbo rẹ̀ ni , a ìlànà ó yàtọ̀ èyí mo ti sọ, obìnrin gbọdọ̀ fi gèlè bo orí rẹ̀ nígbà ó ń sọtẹ́lẹ̀ tàbí ó ń gbàdúrà láàrín ìjọ Ọlọ́run.

Oúnjẹ alẹ́ Olúwa

17 Nínú àwọn àlàkalẹ̀ èmi ko ni yìn yín nítorí péjọ í ṣe fún rere ko ṣe fún búburú. 18 Lọ́kìn-ín-ní, mo gbọ́ pe ìyapa máa ń láàrín yín ìgbà péjọpọ̀ gẹ́gẹ́ ìjọ, mo gba èyí gbọ́ ààyè ibìkan. 19 àní àní, ìyàtọ̀ gbọdọ̀ wa láàrín yín, àwọn ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run láàrín yín le farahàn kedere. 20 Nígbà pàdé láti jẹun, í ṣe oúnjẹ alẹ́ Olúwa ni máa ń jẹ. 21 Ṣùgbọ́n ara yín, nígbà fẹ́ jẹun, olúkúlùkù yín a máa sáré jẹ oúnjẹ rẹ̀ láìdúró de ẹnìkejì rẹ̀. Ebi a máa pa wọ́n, ẹlòmíràn wọ́n ń mu àmuyó àti àmupara. 22 Ṣé ̀yin ilé ti jẹ, ti mu ni? Tàbí ̀yin ń gan ìjọ Ọlọ́run ni? ̀yin ń dójútì àwọn aláìní? Kín ni èmi ó fún un yín? Èmi yóò ha yìn yín nítorí èyí? A! Rárá o. Èmi kọ́, n yìn yín.

23 Nítorí èyí èmi gbà lọ́wọ́ Olúwa ni mo ti fi fún un yin. alẹ́ ọjọ́ Judasi fihàn, Olúwa Jesu Kristi àkàrà. 24 Lẹ́yìn ìgbà ó ti dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún àkàrà náà tan, ó ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó , "gbà jẹ, èyí ara mi a fi fún un yín. máa ṣe eléyìí ni rántí mi." 25 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó ago wáìnì, ó , "Ago yìí ni májẹ̀tuntun nínú ̀jẹ̀ mi, máa ṣe èyí, nígbàkígbà ti ̀yìn ń mu ú, ìrántí mi." 26 Nítorí nígbàkígbà ń jẹ lára àkàrà yìí, ǹ mu nínú ago yìí, ni tún sọ nípa ikú Olúwa. máa ṣe eléyìí títí yóò fi padà .

27 Nítorí náà ẹnikẹ́ni jẹ lára àkàrà yìí, ń mu nínú ago Olúwa yìí, ̀bójúmu, yóò jẹ̀bi ̀ṣẹ̀ ara àti ̀jẹ̀ Olúwa. 28 Ìdí nìyìí ó fi yẹ ènìyàn yẹ ara rẹ̀ dáradára ó jẹ lára àkàrà án àti ó mu nínú ago náà. 29 Nítorí jẹ lára àkàrà, mu nínú ago láìyẹ, ronú ara Kristi àti nǹkan ó túmọ̀ , ̀ ń jẹ, ń ̀bi ìdájọ́ Ọlọ́run sórí ara yín. 30 Ìdí nìyìí ̀pọ̀ yín fi di ẹni lágbára mọ́, ̀pọ̀ yín ń ṣàìsàn, àwọn mìíràn nínú yín tilẹ̀ ti sùn. 31 Ṣùgbọ́n yẹ ara yín dáradára, jẹ ́, a yóò yín lẹ́jọ́. 32 Ṣùgbọ́n nígbà a wa lẹ́jọ́, láti ọwọ́ Olúwa ni a ti , a ba à wa lẹ́bi pẹ̀ayé.

33 Nítorí náà, ̀yin arákùnrin mi ̀wọ́n, nígbàkígbà ti péjọ láti jẹ́ oúnjẹ alẹ́ Olúwa, tàbí fún ìsìn oúnjẹ alẹ́ Olúwa, dúró de ara yín. 34 ebi ń pa ẹnikẹ́ni nínú yin, ó jẹun láti ilé , ó ba á ìjìyà sórí ara rẹ̀ nígbà péjọ.

mo , èmi yóò máa sọ̀rọ̀ lórí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ ìyókù n ì ti fẹnu lẹ́sẹẹsẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-