Publicidade

1 Coríntios 14

̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀ àti ìfèdèfọ̀

1 máa lépa ìfẹ́, ki máa fi ìtara ṣàfẹ́̀bùn í ṣe ti ̀, ṣùgbọ́n ki kúkú máa sọtẹ́lẹ̀. 2 Nítorí ẹni ń sọ̀rọ̀ èdè àìmọ̀, ènìyàn sọ̀rọ̀ ko ṣe Ọlọ́run: nítorí ẹni ó gbọ́; ṣùgbọ́n nípá ti ̀ó ń sọ ohun ìjìnlẹ̀. 3 Ṣùgbọ́n ẹni ń sọtẹ́lẹ̀ ń ba àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ fún ìmúdúró, àti ìgbaniníyànjú, àti ìtùnú. 4 Ẹni ń sọ̀rọ̀ ni èdè àìmọ̀ ń fi ẹsẹ̀ ara rẹ̀ mulẹ̀; ṣùgbọ́n ẹni ti ń sọtẹ́lẹ̀ ń fi ẹsẹ̀ ìjọ múlẹ̀. 5 Ṣùgbọ́n ìbá ki gbogbo yín máa sọ onírúurú èdè, ṣùgbọ́n kúkú máa sọtẹ́lẹ̀, ẹni ń sọtẹ́lẹ̀ pọ̀ ẹni ti ń fèdèfọ̀ lọ, bi kọ ṣe ó ń ṣe ìtumọ̀, ìjọ à kọ́ ̀kọ́.

6 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo àárín yín, mo ń sọ̀rọ̀ èdè àìmọ̀, èrè kín ni èmi yóò jẹ́ fún yin, bi ko ṣe mo ń yín sọ̀rọ̀, yálà nípa ìṣípayá, tàbí ìmọ̀ tàbí nípá ìsọtẹ́lẹ̀, tàbí nípa ̀kọ́? 7 Bẹ́̀ pẹ̀àwọn nǹkan ̀ń dún, ìbá à ṣe fèrè tàbí dùùrù ṣe ìyàtọ̀ nínú wọn, a ó ṣe mọ ohùn fèrè tàbí dùùrù ń ? 8 Nítorí bi ohùn ìpè dájú, ta ni yóò múra fún ogun? 9 Bẹ́̀ ni ̀yin, ṣe ̀yin ń fi ahọ́n yín sọ̀rọ̀ ó ni, a ó ti ṣe mọ ohun ti ń ? Nítorí ̀yin yóò kàn máa sọ̀rọ̀ si afẹ́fẹ́ lásán. 10 Ó jẹ́ onírúurú ohùn èdè ń bẹ ayé, ̀kan ìtumọ̀. 11 Ǹjẹ́ èmí mọ ìtumọ̀ ohùn èdè náà, èmí ó jásí aláìgbédè ẹni ń sọ̀rọ̀, ẹni ń sọ̀rọ̀ yóò jásí aláìgbédè mi. 12 Bẹ́̀ ̀yin, ̀yin ti ìtara fún ̀bùn ̀, máa ṣe àfẹ́àti máa pọ̀ i fún ìdàgbàsókè ìjọ.

13 Nítorí náà jẹ́ ki ẹni ń sọ̀rọ̀ ni èdè àìmọ̀ gbàdúrà ki ó máa ṣe ìtumọ̀ ohun ó sọ. 14 Nítorí èmi ń gbàdúrà èdè àìmọ̀, ̀mi ni ń gbàdúrà, ṣùgbọ́n ọkàn mi jẹ́ aláìléso. 15 14.15: Ef 5.19; Kl 3.16.Ǹjẹ́ kín ni èmi yóò ṣe? Èmi yóò fi ̀mi gbàdúrà, èmi yóò fi òye mi gbàdúrà pẹ̀; Èmi yóò fi ̀mi kọrin, èmi yóò fi òye mi kọrin pẹ̀. 16 14.16: 1Ki 16.36; Sm 106.48; Mt 15.36.bẹ́̀ kọ́, ìwọ yin Ọlọ́run nípa ̀, báwo ni ẹni ń bẹ ni ipò òpè yóò ṣe ṣe "Àmín" si ìdúpẹ́ rẹ, nígbà mọ ohun ìwọ ? 17 Nítorí ìwọ dúpẹ́ gidigidi nítòótọ́, ṣùgbọ́n a fi ẹsẹ̀ ẹnìkejì rẹ múlẹ̀.

18 dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run èmi ń fọ onírúurú èdè ju gbogbo yín lọ. 19 Ṣùgbọ́n mo fẹ́ n kúkú fi ọkàn mi sọ ̀rọ̀ márùn-ún ni inú ìjọ, n kọ́ àwọn ẹlòmíràn ju ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ̀rọ̀ ni èdè àìmọ̀.

20 14.20: Ef 4.14. Ará, ṣe jẹ ọmọdé ni òye, ṣùgbọ́n jẹ́ ọmọdé àrankàn, ṣùgbọ́n ni òye jẹ́ àgbà. 21 14.21: Isa 28.11-12.A kọ ́ nínú òfin ,

"Nípa àwọn aláhọ́n mìíràn

àti elétè àjèjì

èmi ó fi ba àwọn ènìyàn yìí sọ̀rọ̀;

síbẹ̀ wọn yóò gbọ́ tèmi,"

ni Olúwa .

22 Nítorí náà àwọn ahọ́n jásí àmì kan, í ṣe fún àwọn ó gbàgbọ́, ṣe fún àwọn aláìgbàgbọ́: ṣùgbọ́n ìsọtẹ́lẹ̀ í ṣe fún àwọn gbàgbọ́ ṣe fún àwọn ó gbàgbọ́. 23 Ǹjẹ́ gbogbo ìjọ péjọ ibi kan, gbogbo wọn ń fi èdè fọ̀, àwọn ó jẹ́ aláìlẹ́kọ̀́ àti aláìgbàgbọ́ wọlé , wọn yóò ha ̀yin ń ṣe òmùgọ̀? 24 Ṣùgbọ́n gbogbo yín ń sọtẹ́lẹ̀, ti ẹnìkan gbàgbọ́ tàbí ko ni ̀kọ́ wọlé , gbogbo yin yóò fi òye ̀ṣẹ̀ e, gbogbo yin yóò wádìí rẹ̀. 25 Bẹ́̀ a ó fi àṣírí ọkàn rẹ̀ hàn; bẹ́̀ ni òun ó dojúbolẹ̀, yóò sin Ọlọ́run yóò sọ , "Nítòótọ́ Ọlọ́run ń bẹ láàrín yín!"

Ètò ìsìn lẹ́sẹẹsẹ

26 14.26: Ef 5.19. Ǹjẹ́ èéha ti ṣe, kín ni àwa yóò sọ ̀yin ará? Nígbà ̀yin péjọpọ̀, olúkúlùkù yín ni Saamu kan tàbí ̀kọ́ kan, èdè kan, ìfihàn kan àti ìtumọ̀ kan. máa ṣe ohun gbogbo láti gbé ìjọ . 27 ẹnìkan fi èdè fọ̀, ó jẹ ènìyàn méjì, tàbí ó pọ̀ tán, ó jẹ́ mẹ́ta, ó sọ̀rọ̀ ̀kọ̀̀kan, ẹnìkan túmọ̀ rẹ̀. 28 Ṣùgbọ́n ògbufọ̀, ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́ nínú ìjọ; jẹ́ ó máa ara rẹ̀ àti Ọlọ́run sọ̀rọ̀.

29 Jẹ́ àwọn wòlíì méjì tàbí mẹ́ta sọ̀rọ̀, ki àwọn ìyókù wòye ìtumọ̀ ohun a sọ. 30 a fi ohunkóhun hàn ẹni ó jókòó níbẹ̀, jẹ́ ẹni ó kọ́ sọ̀rọ̀ ṣáájú dákẹ́. 31 Nítorí gbogbo yín sọtẹ́lẹ̀ ni ̀kọ̀̀kan, gbogbo yín kọ́ ̀kọ́, a tu gbogbo yín nínú. 32 ̀àwọn wòlíì a máa tẹríba fún àwọn wòlíì. 33 Nítorí Ọlọ́run í ṣe Ọlọ́run ohun rúdurùdu, ṣùgbọ́n ti àlàáfíà. Gẹ́gẹ́ ó ti jẹ́ nínú gbogbo ìjọ ènìyàn mímọ́.

34 14.34: 1Tm 2.11-12; 1Pt 3.1. Jẹ́ ki àwọn obìnrin yín dákẹ́ nínú ìjọ, nítorí a fi fún wọn láti sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ wọn lábẹ́ ìtẹríba, gẹ́gẹ́ òfin pẹ̀ti . 35 wọ́n fẹ́ mọ̀ nípa ohunkóhun, wọn béèrè lọ́wọ́ ọkọ wọn ilé; nítorí ohun ìtìjú ni fún àwọn obìnrin láti máa sọ̀rọ̀ nínú ìjọ.

36 Kín ni? Ṣe lọ́dọ̀ yín ̀rọ̀ Ọlọ́run ti jáde ni, tàbí ̀yin nìkan ni o tọ̀ ? 37 ẹnikẹ́ni ará rẹ̀ òun jẹ́ wòlíì, tàbí òun jẹ́ ẹni ó ̀bùn ̀, jẹ́ nǹkan wọ̀nyí ti mo kọ yin e dájú òfin Olúwa ni wọ́n. 38 Ṣùgbọ́n ẹnìkan fi ojú fo èyí , òun fúnra rẹ̀ a ó fi ojú .

39 Nítorí náà ará, máa fi ìtara ṣàfẹ́láti sọtẹ́lẹ̀, ṣe dánilẹ́kun láti fi èdè fọ̀. 40 máa ṣe ohun gbogbo tẹ̀yẹtẹ̀yẹ àti lẹ́sẹẹsẹ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-