Publicidade

1 Coríntios 4

Àwọn aposteli Kristi

1 Nítorí náà, ṣe yẹ ènìyàn máa gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́ àti ìríjú a fún ni oore-ọ̀fẹ́ láti mọ Kristi a fún oore-ọ̀fẹ́ láti mọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run. 2 Òun kan náà ó tọ́ fún ìríjú, ni ó jẹ́ olóòtítọ́. 3 Ṣùgbọ́n ohun kíkíní ni fún mi , máa ṣe ìdájọ́ mi, tàbí a máa ṣe ìdájọ́ nípa ìdájọ́ ènìyàn; nítòótọ́, èmi tilẹ̀ ara mi lẹ́jọ́. 4 Nítorí ̀ọkàn mi mi ̀bi; ṣùgbọ́n a ti ipa èyí mi láre, ṣùgbọ́n Olúwa ni ẹni ń ṣe ìdájọ́ mi. 5 Nítorí náà, ṣe ṣe ìdájọ́ ohunkóhun, Olúwa padà , ẹni yóò ohunkóhun ó fi ara sin ìmọ́lẹ̀, yóò fi ìmọ̀ ọkàn ènìyàn hàn, nígbà náà ni olúkúlùkù yóò ìyìn tirẹ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

6 kíyèsi i , mo ti fi ara mi àti Apollo ṣe àpẹẹrẹ nǹkan mo , ̀yin ti ipa wa kọ́ láti máa ṣe ohun a ti kọ̀kọjá. "ẹnikẹ́ni nínú yín ṣe tìtorí ẹnìkan gbéraga ẹnìkejì." 7 Nítorí ta ni ó yàtọ̀ àwọn ẹlòmíràn? ni ìwọ ni ìwọ gbà? ìwọ ba gbà á, èétiṣe ìwọ fi ń halẹ̀ ẹni ìwọ gba á?

8 Ni báyìí ohun gbogbo ń fẹ́! Báyìí ti di ọlọ́rọ̀! ti di ọba. Lójú yín, àwa ti di ẹni ̀yìn. Ìbá dùn mọ́ mi ó jẹ́ lóòtítọ́ ni ti di ọba lórí ìtẹ́ yín: a ó máa jẹ ọba pẹ̀yín! 9 Nítorí mo Ọlọ́run ń fi àwa aposteli hàn ìkẹyìn ẹni a lẹ́bi ikú àwọn, nítorí a fi ṣe ìran fún àwọn ènìyàn àti àwọn angẹli àti gbogbo ayé. 10 Àwa jẹ́ aṣiwèrè nítorí Kristi, ṣùgbọ́n ̀yin jẹ́ ọlọ́gbọ́n nínú Kristi! Àwa jẹ́ aláìlera, ṣùgbọ́n ̀yin jẹ́ alágbára! ̀yin jẹ́ ẹni àyẹ́, àwa jẹ ẹni ̀gàn! 11 Títí di wákàtí yìí ni a ń rìn kiri nínú ebi àti òǹgbẹ, a n wọ aṣọ àkísà, a ń wa, a ibùgbé kan. 12 a ń fi ọwọ́ ara wa ṣiṣẹ́, wọn ń gàn wa, àwa ń súre, wọn ń ṣe inúnibíni wa, àwa ń forítì i. 13 Wọn ń kẹ́gàn wa, àwa ń bẹ̀bẹ̀. Títí di ìsinsin yìí ni a ti ohun ̀gbin ayé, orí àkìtàn gbogbo ayé.

14 Èmi kọ̀nǹkan wọ̀nyí láti fi dójútì yín, ṣùgbọ́n láti kìlọ̀ fún un yín àwọn ọmọ mi mo yàn fẹ́. 15 Nítorí ̀yin tilẹ̀ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) olùkọ́ni nínú Kristi, ṣùgbọ́n ̀yin ni baba púpọ̀; nítorí nínú Kristi Jesu ni mo jẹ́ baba fún un yín nípasẹ̀ ìyìnrere. 16 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, máa ṣe àfarawé mi. 17 Nítorí náà ni mo ṣe rán Timotiu i yín, ẹni í ṣe ọmọ mi olùfẹ́ àti olódodo nínú Olúwa, ẹni yóò máa yín rántí ̀mi ó nínú Kristi Jesu, gẹ́gẹ́ mo ti ń kọ́ni nínú gbogbo ìjọ níbi gbogbo.

18 Mo mọ̀ àwọn mìíràn nínú yín ya onígbèéraga ènìyàn, wọn ń ̀ń mi láti sọ́dọ̀ yín. 19 Ṣùgbọ́n èmi yóò tọ̀ yín àìpẹ́ yìí Olúwa fẹ́; èmi yóò ṣe ìwádìí àwọn agbéraga yìí ṣe ń sọ̀rọ̀ àti agbára wọ́n . 20 Nítorí ìjọba Ọlọ́run í ṣe nínú ̀rọ̀, ṣe nínú agbára. 21 Èwo ni yàn? ń sọ́dọ̀ yín pẹ̀pàṣán, tàbí ni ìfẹ́, àti ̀tútù?

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-