Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kọrinti 6

15 6.15: Ro 12.5; 1Kọ 12.27.Ṣé tilẹ̀ mọ̀ ara yín gan an jẹ́ ̀ara Kristi fún ara rẹ̀? Ǹjẹ́ ó ba jẹ́ bẹ́̀, ǹjẹ́ ó yẹ ń ̀ara Kristi ń fi ṣe ̀ara àgbèrè ? a i! 16 6.16: Gẹ 2.24; Mt 19.5; Mk 10.8; Ef 5.31.Tàbí mọ̀ ẹnìkan so ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ àgbèrè ó jẹ́ ara kan pẹ̀rẹ̀? Nítorí a kọ ́ , "Àwọn méjèèjì yóò di ara kan." 17 6.17: Jh 17.21-23; Ro 8.9; Ga 2.20.Ṣùgbọ́n ẹni ti ó dàpọ̀ mọ́ Olúwa di ̀kan náà pẹ̀rẹ̀.

18 máa fún àgbèrè. Gbogbo ̀ṣẹ̀ ènìyàn ń lóde ara, ṣùgbọ́n ẹni ń ṣe àgbèrè ń ṣe ara òun tìkára rẹ̀. 19 6.19: 1Kọ 3.16; Jh 2.21.Tàbí, ̀yin mọ̀ ara yín ni tẹmpili ̀Mímọ́, ti ń bẹ nínú yín, ti ̀yin ti gbà lọ́wọ́ Ọlọ́run? ̀yin í ṣe ti ara yín, 20 6.20: 1Kọ 7.23; Ap 20.28; Ro 12.1.nítorí a ti yín ni iye kan. Nítorí náà yìn Ọlọ́run lógo nínú ara yín, àti nínú ̀yín, í ṣe ti Ọlọ́run.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também