Publicidade

1 Coríntios 9

Àwọn ̀tọ́ aposteli

1 9.1: 1Kọ 9.19; 2Kọ 12.12; 1Tẹ 2.6; Ap 9.3,17; 1Kọ 15.8. Èmi ha ni òmìnira ? Èmi ha ń ṣe aposteli ? Èmi ha ti Jesu Olúwa ? ̀yìn ha kọ́ èrè iṣẹ́ mi nínú Olúwa ? 2 ìrònú àwọn ẹlòmíràn, èmi í ṣe aposteli. Dájúdájú aposteli ni mo jẹ́ fún un yín, n ṣe fún àwọn ẹlòmíràn. Nítorí èdìdì iṣẹ́ aposteli mi ni ̀yin jẹ́ nínú Olúwa.

3 Èyí ni ìdáhùn mi àwọn ń béèrè ̀tọ́ aposteli mi. 4 9.4: 1Kọ 9.14.Ṣé a ̀tọ́ láti máa jẹ àti láti máa mu ? 5 9.5: 1Kọ 7.7-8; Mt 12.46; 8.14; Jh 1.42.Ṣé àwa ̀tọ́ láti máa ìyàwó í ṣe onígbàgbọ́ káàkiri gẹ́gẹ́ àwọn aposteli mìíràn? Àti arákùnrin Olúwa, àti Kefa. 6 9.6: Ap 4.36.Ṣé èmi nìkan àti Barnaba, àwa ha agbára láti máa ṣiṣẹ́ bọ́ ara wa ni?

7 Ta ni ó ṣíṣẹ́ ológun ó sanwó ara rẹ̀? Ta gbin ọgbà àjàrà í jẹ nínú èso rẹ̀? Tàbí ta ń bọ ̀wọ́ ẹran í ì jẹ nínú wàrà ̀wọ́ ẹran? 8 Èmi ha sọ nǹkan wọ̀nyí ènìyàn? Tàbí òfin bákan náà ? 9 9.9: De 25.4; 1Tm 5.18.Nítorí nínú òfin Ọlọ́run fún Mose, ni a kọ ́ , "Ìwọ gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu." Ǹjẹ́ màlúù ni Ọlọ́run n ṣe ìtọ́rẹ̀ bi? 10 9.10: 2Tm 2.6.Dájúdájú ó sọ eléyìí fún wa , nítorí wa ni a ṣe kọ̀yìí ẹni ń tulẹ̀ máa tulẹ̀ ìrètí àti ẹni ń pakà ni ìrètí láti ìpín nínú ìkórè. 11 9.11: Ro 15.27.àwa ti fún irúgbìn ohun ti ̀sínú ọkàn yín, ohun ńlá ha ni àwa ó ba ohun ti yín ṣe ti ara? 12 9.12: 2Kọ 6.3.àwọn ẹlòmíràn ̀tọ́ ìrànlọ́wọ́ láti ̀dọ̀ yín, àwa ha kọ́ ni ó tọ́ ?

Ṣùgbọ́n àwa lo agbára yìí ṣùgbọ́n àwa faradà ohun gbogbo, àwa ba à ṣe ìdènà fún ìyìnrere Kristi.

13 9.13: De 18.1. Ǹjẹ́ ó e yín Ọlọ́run sọ fún àwọn ó ń ṣiṣẹ́ nínú tẹmpili wọ́n oúnjẹ tàbí àwọn ̀bùn wọ́n fún òun, láti fi ṣe ìtọ́ara wọn? Àti àwọn ń dúró pẹpẹ wọn a máa ṣe àjọpín pẹ̀pẹpẹ. 14 9.14: Mt 10.10; Lk 10.7-8.Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni Olúwa ti fi àṣẹ lélẹ̀ , àwọn ń wàásù ìyìnrere wọn máa jẹ́ nípa ìyìnrere.

15 9.15: 2Kọ 11.10. Síbẹ̀síbẹ̀ n ì ì lo irú àwọn ̀tọ́ wọ̀nyí . Bẹ́̀ ni èmi kọ ìwé yìí láti fi sọ fún un yín , mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ í gbà irú nǹkan bẹ̀ ́ lọ́wọ́ yín. a sọ òtítọ́, ó sàn fún mi láti sínú ebi ju n sọ ògo mo láti wàásù . 16 Nítorí mo ti ń wàásù ìyìnrere, í ṣe ohun mo máa ṣògo . Èmi tilẹ̀ le è ṣe é , a tilẹ̀ sọ mo fẹ́ kọ̀ ́ sílẹ̀. Ègbé ni fún mi mo kọ̀ láti wàásù ìyìnrere. 17 9.17: 1Kọ 4.1; Ga 2.7.jẹ́ ń wàásù tinútinú mi, mo èrè kan, ṣùgbọ́n ń ṣe tinútinú mi, a ti fi iṣẹ́ ìríjú mi lọ́wọ́. 18 9.18: 2Kọ 11.7.irú ipò báyìí, kín ni yóò jẹ èrè mi ni láti jẹ́? Èrè mi àgbàyanu ayọ̀ mo ń gbà nípa ìwàásù ìyìnrere láìgba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, láìbéèrè ̀tọ́ mi lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.

19 mo ti jẹ́ òmìnira ń darapọ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni, mo sọ ara mi di ẹrú lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn, láti jèrè ̀pọ̀lọpọ̀ i. 20 9.20: Ro 11.14.Nígbà lọ́dọ̀ àwọn Júù, mo dàbí ̀kan nínú wọn, wọn ba à tẹ́ìwàásù ìyìnrere mi àti ki n le jèrè wọn fún Kristi. Nígbà mo láàrín àwọn lábẹ́ òfin èmi í wọn jiyàn rárá (ó tilẹ̀ jẹ́ èmi lábẹ́ òfin), èmi jèrè àwọn ti ń bẹ lábẹ́ òfin. 21 9.21: Ro 2.12,14.Nígbà mo láàrín àwọn lábẹ́ òfin, èmi náà yóò dàbí ẹni lábẹ́ òfin (èmi í ṣe aláìlófin Ọlọ́run, ṣùgbọ́n èmí ń bẹ lábẹ́ òfin Kristi), èmi le jèrè àwọn lábẹ́ òfin. 22 9.22: 2Kọ 11.29; Ro 15.1; 1Kọ 10.33; Ro 11.14.Nígbà mo láàrín àwọn aláìlera, èmi náà yóò di aláìlera, èmi jèrè àwọn aláìlera. Mo di ohun gbogbo fún gbogbo ènìyàn, èmi ba à gba díẹ̀ lábẹ́ ó ti ó . 23 Èmi ń ṣe ohun gbogbo nítorí ti ìyìnrere, èmi ó jẹ́ alábápín nínú rẹ̀ pẹ̀yín.

24 9.24: Hb 12.1. ̀yin mọ̀ , olúkúlùkù ẹni ó ipa nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ̀bùn ó ga . Nítorí náà, eré ìje yín ba à le borí. 25 9.25: 2Tm 2.5; 4.8; Jk 1.12; 1Pt 5.4.Gbogbo ẹni ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ìdíbàjẹ́. Ṣùgbọ́n àwa ń eré ìje tiwa láti fi gba adé ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé. 26 Nítorí náà, mo ń eré ìje lọ sójú àmì, í ṣe ẹni ti lójú. ń n borí, í ṣe ẹni ń afẹ́fẹ́ . 27 Ṣùgbọ́n èmi ń ara mi ìjánu, mo ń un abẹ́ ìtẹríba, lẹ́yìn mo ti wàásù fún àwọn ẹlòmíràn, nítorí ohunkóhun, èmi fún rara mi ṣe di ẹni ìtanù fún ̀bùn náà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-