Publicidade

1 João 3

1 3.1: Jh 1.12; 16.3. wo irú ìfẹ́ Baba fi fẹ́ wa, a fi ń ọmọ Ọlọ́run; bẹ́̀ ni a à jẹ́. Nítorí èyí ni ayé ṣe mọ̀ , nítorí mọ̀ ́n. 2 Olùfẹ́, ọmọ Ọlọ́run ni àwa ń ṣe nísinsin yìí, a ì i fihàn àwa ó ti : àwa mọ̀ , nígbà òun ba farahàn, àwa yóò dàbí rẹ̀; nítorí àwa yóò i, àní òun . 3 Olúkúlùkù ẹni ó ba ìrètí yìí nínú rẹ̀, ń wẹ ara rẹ̀ mọ́, àní òun ti mọ́.

4 Ẹnikẹ́ni ó ń dẹ́ṣẹ̀, ó ń òfin pẹ̀, nítorí ̀ṣẹ̀ ni rírú òfin. 5 3.5: Jh 1.29.̀yin mọ̀ , òun farahàn láti mu ̀ṣẹ̀ kúrò; ̀ṣẹ̀ ṣí nínú rẹ̀. 6 Ẹnikẹ́ni ó ba ń gbé inú rẹ̀ í dẹ́ṣẹ̀; ẹnikẹ́ni ó ń dẹ́ṣẹ̀ i, bẹ́̀ ni mọ̀ ́n.

7 ̀yin ọmọ mi, ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni tàn yín, ẹni ó ń ṣe òdodo, ó jásí olódodo, gẹ́gẹ́ òun jẹ olódodo. 8 3.8: Jh 8.34,44.Ẹni ó ba ń dẹ́ṣẹ̀ èṣù ni; nítorí láti àtètèkọ́ṣe ni èṣù ti ń dẹ́ṣẹ̀. Nítorí èyí ni Ọmọ Ọlọ́run ṣe farahàn, ó pa iṣẹ́ èṣù run. 9 3.9: 1Jh 5.18.Ẹnikẹ́ni a ti ipa Ọlọ́run , í dẹ́ṣẹ̀; nítorí irú rẹ̀ ń gbé inú rẹ̀, dẹ́ṣẹ̀ nítorí a ti ti ipa Ọlọ́run i. 10 Nínú èyí ni àwọn ọmọ Ọlọ́run ń farahàn, àti àwọn ọmọ èṣù; ẹnikẹ́ni ba ń ṣe òdodo, àti ẹni fẹ́ràn arákùnrin rẹ̀ í ṣe ti Ọlọ́run.

Fẹ́ràn ọmọnìkejì rẹ

11 3.11: 1Jh 1.5. Nítorí èyí ni iṣẹ́ ̀yin gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, ki àwa fẹ́ràn ara wa. 12 í ṣe Kaini, í ṣe ẹni búburú, o pa arákùnrin rẹ̀. Nítorí kín ni ó ṣe pa á? Nítorí iṣẹ́ tirẹ̀ jẹ́ búburú ṣùgbọ́n arákùnrin rẹ̀ jẹ́ òdodo. 13 3.13: Jh 15.18-19.ẹnu ṣe yín, ̀yin ará mi, ayé kórìíra yín. 14 3.14: Jh 5.24.Àwa mọ̀ àwa rékọjá láti inú ikú sínú ìyè, nítorí àwa fẹ́ràn àwọn ará. Ẹni ba ni ìfẹ́, ó ń gbé inú ikú. 15 Ẹnikẹ́ni ó ba kórìíra arákùnrin rẹ̀ apànìyàn ni, ̀yin mọ́ apànìyàn ó ni ìyè àìnípẹ̀kun láti máa gbé inú rẹ̀.

16 3.16: Jh 13.1; 15.13. Nípa èyí ni àwa mọ ìfẹ́ nítorí ó fi ̀rẹ̀ lélẹ̀ fún wa, ó yẹ àwa fi ̀wa lélẹ̀ fún àwọn ará. 17 Ṣùgbọ́n ẹni ó ni ohun ìní ayé, ó ri arákùnrin rẹ̀ ó ṣe aláìní, ó ìlẹ̀kùn ìyọ́rẹ̀ mọ́ ọn, báwo ni ìfẹ́ Ọlọ́run ṣe ń gbé inú rẹ̀? 18 3.18: Jk 1.22.̀yin ọmọ mi, ṣe jẹ́ a fi ̀rọ̀ tàbí ahọ́n fẹ́ràn, ṣe ni ìṣe àti òtítọ́.

19 Àti nípa èyí ni àwa ó mọ̀ àwa jẹ́ ti òtítọ́, àti àwa ó fi ọkàn ara wa balẹ̀ níwájú rẹ̀. 20 Nínú ohunkóhun ọkàn wa ń wa lẹ́bi; nítorí Ọlọ́run tóbi ju ọkàn wa lọ, ó mọ ohun gbogbo. 21 3.21: 1Jh 5.14.Olùfẹ́, ọkàn wa wa lẹ́bi, ǹjẹ́ àwa ni ìgboyà níwájú Ọlọ́run? 22 Àti ohunkóhun àwa béèrè, ni àwa ń gbà lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí àwa ń pa òfin rẹ̀ mọ́, àwa ń ṣe àwọn nǹkan ó dára lójú rẹ̀. 23 3.23: Jh 6.29; 13.34; 15.17.Èyí ni òfin rẹ̀, àwa gba orúkọ Jesu Kristi Ọmọ rẹ̀ gbọ́, a fẹ́ràn ara gẹ́gẹ́ ó fi òfin fún wa. 24 3.24: 1Jh 4.13.Ẹni ó pa òfin rẹ̀ mọ́ ń gbé inú rẹ̀, àti òun nínú rẹ̀. Àti nípa èyí ni àwa mọ̀ ó ń gbé inú wa, nípa ̀ó fi fún wa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-