Publicidade

1 Tessalonicenses 5

6 5.6: Ro 13.11; 1Pt 1.13.Nítorí náà, kíyèsára yín ṣe sùn àwọn ẹlòmíràn. máa ṣọ́máa pa ara yín mọ́. 7 5.7: Ap 2.15; 2Pt 2.13.Nítorí àwọn wọ́n ń sùn, a máa sùn òru, àwọn ẹni ń mu àmupara, a máa un òru. 8 5.8: Ef 6.17; Ro 8.24.Ṣùgbọ́n àwa jẹ́ ti ìmọ́lẹ̀, jẹ́ a pa ara wa mọ́, gbígbé ìgbàgbọ́ wọ̀ àti ìfẹ́ ìgbàyà ni òru àti ìrètí ìgbàlà àṣíborí. 9 5.9: 1Tẹ 1.10; 2Tẹ 2.13; Ro 14.9.Nítorí , Ọlọ́run yàn wa láti da ìbínú rẹ̀ gbígbóná orí wa, ṣùgbọ́n ó yàn láti gbà nípasẹ̀ Olúwa wa, Jesu Kristi.

Veja também

1 Tessalonicenses
Ver todos os capítulos de 1 Tessalonicenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-