Publicidade

Amós 3

̀jíjẹ́ nípa àwọn ọmọ Israẹli

1 gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ti sọ nípa rẹ̀, ̀yin ènìyàn Israẹli nípa àwọn ìdílé mo jáde láti Ejibiti:

2 "Ìwọ nìkan ni ẹni mo yàn

nínú gbogbo àwọn ìran ayé yìí;

nígbà náà èmi ó jẹ ́

fún gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ."

3 Ẹni méjì ha à le rìn pọ̀

láìjẹ́ wọ́n ti pinnu láti ṣe bẹ?

4 Ǹjẹ́ Kìnnìún yóò ha ramúramù nínú igbó,

ohun ọdẹ?

Ọmọ kìnnìún yóò ha jáde nínú ìhó rẹ̀

ohun kan ?

5 Ǹjẹ́ ẹyẹ ṣubú sínú okùn ọdẹ lórí ilẹ̀

nígbà a dẹ okùn ọdẹ fún un?

Okùn ọdẹ ha jáde lórí ilẹ̀

nígbà ohun yóò ?

6 Nígbà ìpè dún ìlú,

àwọn ènìyàn ha bẹ̀?

ewu wa lórí ìlú

ha ṣe Olúwa ni ó á?

7 Nítòótọ́ Olúwa Olódùmarè ṣe ohun kan

láìfi èrò rẹ̀ hàn

fun àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀.

8 Kìnnìún ti ramúramù

ta ni yóò bẹ̀?

Olúwa Olódùmarè ti sọ̀rọ̀

ta ni le ṣe àìsọ àsọtẹ́lẹ̀?

9 kéde ààfin Aṣdodu

àti ààfin ilẹ̀ Ejibiti.

"ara yín jọ orí òkè ńlá Samaria;

wo ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láàrín rẹ̀

àti ìnilára láàrín àwọn ènìyàn rẹ."

10 "Wọn mọ wọ́n ṣe ń ṣe rere," ni Olúwa ,

"àwọn ẹni ó gba àwọn ìwà ipá àti olè ààfin rẹ̀."

11 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

"Àwọn ̀yóò pa ilẹ̀ náà run;

yóò ibi gíga yín palẹ̀

a ó ba ààfin rẹ̀ jẹ́."

12 Èyí ni ohun Olúwa :

"olùṣọ́-àgùntàn ti ń gbà itan méjì

kúrò ẹnu kìnnìún tàbí ̀etí kan

bẹ́̀ ni a ó àwọn ọmọ Israẹli,

ń gbé Samaria kúrò

igun ibùsùn wọn

orí àga ìrọ̀gbọ̀wọn Damasku."

13 "Gbọ́ èyí o jẹ́rìí nípa ilé Jakọbu," ni Olúwa , Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun.

14 "ọjọ́ mo fìyà jẹ Israẹli lórí ̀ṣẹ̀ wọn,

Èmi yóò pa pẹpẹ Beteli run;

ìwo pẹpẹ ni a ó kúrò

yóò lulẹ̀.

15 Èmi yóò ilé òtútù

lulẹ̀ pẹ̀ilé ooru;

ilé a fi eyín erin ṣe lọ́ṣọ̀́ yóò ṣègbé

a ó pa ilé ńlá náà run,"

ni Olúwa .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-