Publicidade

Amós 5

o

1 Gbọ́ ̀rọ̀ yìí, ìwọ ilé Israẹli, ìpohùnréré ẹkún mo ṣe nípa rẹ:

2 "Wúńdíá Israẹli ṣubú

láì le padà dìde

ó di ẹni ìkọ̀ilẹ̀ rẹ̀

ẹni yóò gbé e dìde."

3 Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè :

"Ìlú ẹgbẹ̀rún (1,000) alágbára ti jáde,

yóò dín ku ọgọ́rùn-ún Israẹli.

Ìlú ọgọ́rùn-ún alàgbà ti jáde

yóò ṣẹ́ẹni mẹ́wàá."

4 Èyí ni ohun Olúwa sọ fún ilé Israẹli:

"mi o ;

5 ṣe Beteli,

ṣe lọ Gilgali,

ṣe rìnrìn àjò lọ Beerṣeba.

Nítorí dájúdájú a ó Gilgali ìgbèkùn,

A ó sọ Beteli di asán."

6 Olúwa, ̀yin yóò ,

ó ba à gbilẹ̀ iná Josẹfu

a o run

Beteli ẹni yóò bu omi pa á.

7 ̀yin ̀ sọ òdodo di ìkorò

gbé olódodo ṣánlẹ̀.

8 Ẹni ó ìràwọ̀ Pleiadesi àti Orioni

ẹni ó sọ òru dúdú di òwúrọ̀

ó sọ ọjọ́ dúdú di ìmọ́lẹ̀

ẹni ó wọ́ omi Òkun jọ pọ̀

ó rọ̀ wọ́n orí ilẹ̀

Olúwa ni orúkọ rẹ̀,

9 Ó fọ́n ìparun ìlú olódi

ó sọ àwọn ibùgbé àwọn ọmọ-aládé di ahoro.

10 Ìwọ kórìíra ẹni ń ni ẹnu ibodè

ó ń pẹ̀gàn ẹni ń sọ òtítọ́.

11 Ìwọ ń tẹ tálákà mọ́lẹ̀

o ń fi ipá gba ọkà lọ́wọ́ wọn.

Nítorí náà, ìwọ ti fi òkúta a gbẹ́ kọ́

ṣùgbọ́n gbé inú wọn,

Nítòótọ́ ìwọ ti gbin ọgbà àjàrà ó lẹ́.

Ìwọ mu wáìnì inú wọn.

12 Nítorí mo mọ iye àìṣedéédéé rẹ

mo mọ ̀ṣẹ̀ rẹ tóbi .

Ìwọ ni olódodo lára, ìwọ ń gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀

o ń fi òtítọ́ du tálákà ilé ẹjọ́.

13 Àwọn ọlọ́gbọ́n máa ń dákẹ́ jẹ́́ àkókò wọ̀nyí,

nítorí búburú ni gbogbo ọjọ́.

14 rere, ṣe búburú

ìwọ ba à le .

Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun yóò pẹ̀rẹ.

Òun yóò pẹ̀rẹ ìwọ ṣe .

15 Kórìíra búburú o fẹ́ rere

dúró orí òtítọ́ ilé ẹjọ́

bóyá Olúwa Ọlọ́run alágbára

yóò síjú àánú wo ọmọ Josẹfu ṣẹ́.

16 Nítorí èyí ni ohun Olúwa, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun :

"Ẹkún yóò àwọn òpópónà

igbe ìnira yóò àwọn gbàgede ìlú.

A ó àwọn àgbẹ̀ jọ láti sọkún

àti àwọn ń ṣọ̀fọ̀ láti pohùnréré ẹkún.

17 Ìpohùnréré ẹkún yóò gbogbo ọgbà àjàrà,

nítorí èmi yóò la àárín yín kọjá,"

ni Olúwa .

Ọjọ́ Olúwa

18 Ègbé ni fún ìwọ ó pẹ́

nítorí ọjọ́ Olúwa

ni ìwọ fi pẹ́ fún ọjọ́ Olúwa?

Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn ojú ọjọ́.

19 Gẹ́gẹ́ ènìyàn ó fún kìnnìún,

ó padà bọ́ ẹnu àmọ̀tẹ́kùn.

Yóò dàbí ẹni ó wọ ilé rẹ̀ lọ

ó sinmi ògiri ilé rẹ̀

ejò ú ṣán.

20 Ǹjẹ́ ọjọ́ Olúwa ha ṣókùnkùn dípò ó ìmọ́lẹ̀?

yóò ṣókùnkùn dúdú láìsí ìmọ́lẹ̀ kankan níbẹ̀.

21 "Mo kórìíra, mo kẹ́gàn àwọn àsè ̀sìn in yín,

Èmi inú dídùn àpéjọ yín.

22 ó tilẹ̀ jẹ́ ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà .

Èmi tẹ́wọ́ gbà wọ́n.

ó tilẹ̀ jẹ́ àṣàyàn ọrẹ àlàáfíà .

Èmi náání wọn.

23 gbé ariwo orin yín sẹ́yìn!

Èmi fetísí ohun èlò orin yín.

24 Jẹ́ òtítọ́ sàn odò

àti òdodo ìsun è gbẹ!

25 "Àbí ̀yin ẹbọ àti ọrẹ tọ̀

ogójì ọdún aginjù ìwọ ilé Israẹli?

26 ̀yin ti gbé ibi ìrúbọ àwọn ọba yín sókè,

ibùgbé àwọn òrìṣà yín,

àní, ti àwọn òrìṣà yín ó níyì jùlọ,

èyí ̀yin fi ọwọ́ ara yín ṣe.

27 Nítorí náà èmi yóò rán an yín lọ ìgbèkùn ìkọjá Damasku,"

ni Olúwa , ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ọlọ́run alágbára.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-