Publicidade

Apocalipse 22

Omi iyè

1 Ó fi odò omi ìyè kan hàn mi, ó mọ́ kirisitali, ń ibi ìtẹ́ Ọlọ́run àti ̀dọ́-Àgùntàn jáde , 2 àárín ìgboro rẹ̀, àti níhà èkínní kejì odò náà, ni igi ìyè gbé , o máa ń so onírúurú èso méjìlá, a máa so èso rẹ̀ ni oṣooṣù ewé igi náà fún mímú àwọn orílẹ̀-èdè láradà. 3 Ègún yóò ṣí mọ: ìtẹ́ Ọlọ́run àti ̀dọ́-àgùntàn ni yóò máa níbẹ̀; àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò máa sìn ín. 4 Wọ́n ó si máa ojú rẹ̀; orúkọ rẹ̀ yóò si máa ni iwájú orí wọn. 5 Òru yóò mọ́; wọn wa ìmọ́lẹ̀ fìtílà, tàbí ìmọ́lẹ̀ oòrùn; nítorí Olúwa Ọlọ́run ni yóò tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn: wọn ó máa jẹ ọba láé àti láéláé.

6 Ó fún mi , "Òdodo àti òtítọ́ ni ̀rọ̀ wọ̀nyí: Olúwa Ọlọ́run ̀àwọn wòlíì ni ó ran angẹli rẹ̀ láti fi ohun ó láti ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí hàn àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀."

7 "Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán! Ìbùkún ni fún ẹni ń pa ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí mọ́!"

8 Èmi, Johanu, ni ẹni ó gbọ́ ó ri nǹkan wọ̀nyí. Nígbà mo gbọ́ mo , mo wólẹ̀ láti foríbalẹ̀ níwájú ẹsẹ̀ angẹli náà, o fi nǹkan wọ̀nyí hàn mi. 9 Nígbà náà ni ó fún mi , "ò, ṣe bẹ́̀, ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ ni èmi, àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ wòlíì, àti ti àwọn ń pa ̀rọ̀ inú ìwé yìí mọ́. Foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run!"

10 Ó fún mi , "ṣe fi èdìdì di ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí, nítorí ìgbà dẹ̀dẹ̀. 11 Ẹni ń ṣe aláìṣòótọ́, ó máa ṣe aláìṣòótọ́ ; àti ẹni ń ṣe ẹlẹ́gbin, ó máa ṣe ̀gbin ; àti ẹni ń ṣe olódodo, ó máa ṣe òdodo ; àti ẹni ń ṣe mímọ́, ó máa ṣe mímọ́ ."

Ìkádìí: Ìpeni àti ìkìlọ̀

12 "Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè ń bẹ pẹ̀mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀ yóò . 13 Èmi ni Alfa àti Omega, ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin.

14 "Ìbùkún ni fún àwọn ti ń fọ aṣọ wọn, wọ́n ni ̀tọ́ láti ibi igi ìyè náà, àti wọ́n gbà àwọn ẹnu ibodè wọ inú ìlú náà. 15 Nítorí ni òde ni àwọn ajá gbé , àti àwọn oṣó, àti àwọn àgbèrè, àti àwọn apànìyàn, àti àwọn abọ̀rìṣà, àti olúkúlùkù ẹni ó fẹ́ràn èké ó ń hùwà èké.

16 "Èmi, Jesu, ni ó rán angẹli mi láti jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí fún yin àwọn ìjọ. Èmi ni gbòǹgbò àti irú-ọmọ Dafidi, àti ìràwọ̀ òwúrọ̀ ń tàn."

17 ̀àti ìyàwó , "Máa bọ!" Àti ẹni ó ń gbọ́ ó , "Máa bọ̀!" Àti ẹni òǹgbẹ ń gbẹ ó , àti ẹni o fẹ́, ó gba omi ìyè náà lọ́fẹ̀́.

18 Èmi kìlọ̀ fún olúkúlùkù ẹni ń gbọ́ ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí , ẹnikẹ́ni ba fi kún wọn, Ọlọ́run yóò fi kún àwọn ìyọnu a kọ sínú ìwé yìí fún un. 19 ẹnikẹ́ni kúrò nínú ̀rọ̀ ìwé ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, Ọlọ́run yóò ipa tirẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, àti kúrò nínú ìlú mímọ́ náà, àti kúrò nínú àwọn ohun a kọ sínú ìwé yìí.

20 Ẹni ó jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí , "Nítòótọ́ èmi ń bọ̀ kánkán."

Àmín. Máa bọ̀, Jesu Olúwa!

21 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Olúwa ó pẹ̀gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. Àmín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-