Publicidade

Apocalipse 6

Ṣí àwọn èdìdì ìwé náà

1 Èmi i nígbà ̀dọ́-àgùntàn náà ṣí ọkàn nínú èdìdì wọ̀nyí, mo gbọ́ ̀kan nínú àwọn ̀alààyè mẹ́rin náà ń sísán àrá , ", ó!" 2 6.2: Sk 1.8; 6.1-3.Mo ó, kíyèsi i, ẹṣin funfun kan: ẹni ó jókòó lórí i rẹ̀ ọfà kan; a fi adé kan fún un: ó jáde lọ láti ìṣẹ́gun ìṣẹ́gun.

3 Nígbà ó ṣí èdìdì kejì, mo gbọ́ ohùn ̀alààyè , ", ó!" 4 Ẹṣin mìíràn ó pupa jáde, a fi agbára fún ẹni ó jókòó lórí rẹ̀, láti gba àlàáfíà kúrò lórí ilẹ̀ ayé, àti wọn ó máa pa ara wọn, a fi idà ńlá kan e lọ́wọ́.

5 Nígbà ó di èdìdì kẹta, mo gbọ́ ohùn ̀alààyè kẹta , "ó". Mo ó, kíyèsi i, ẹṣin dúdú kan; ẹni ó jókòó lórí rẹ̀ ìwọ̀n aláwẹ́ méjì ọwọ́ rẹ̀. 6 6.6: 2Ọb 6.25.Mo gbọ́ ẹni ohùn kan àárín àwọn ̀alààyè mẹ́rẹ̀̀rin ti ń , òsùwọ̀n alikama kan fún owó idẹ kan, àti òsùwọ̀n ọkà barle mẹ́ta fún owó idẹ kan, kíyèsi i, ó ṣe pa òróró àti ọtí wáìnì lára.

7 Nígbà ó ṣí èdìdì kẹrin, mo gbọ́ ohùn ̀alààyè kan , "ó!" 8 6.8: Ho 13.14; El 5.12.Mo ó, kíyèsi, ẹṣin ràndànràndàn kan, orúkọ ẹni ó jókòó lórí rẹ̀ ni ikú, àti ipò òkú tọ̀ ́ lẹ́yìn. A fi agbára fún wọn lórí ìdámẹ́rin ayé, láti fi idà, àti ebi, àti ikú, àti ẹranko lu orí ilẹ̀ ayé pa.

9 Nígbà ó ṣí èdìdì karùn-ún, mo lábẹ́ pẹpẹ, ọkàn àwọn a ti pa nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti nítorí ̀wọ́n dìímú, 10 6.10: Sk 1.12; Sm 79.5; Gẹ 4.10.Wọ́n kígbe ohùn rara, , "Yóò ti pẹ́ , Olúwa Olódùmarè, ẹni mímọ́ àti olóòtítọ́ ìwọ yóò ṣe ìdájọ́ o gbẹ̀san ̀jẹ̀ wa mọ́ lára àwọn ń gbé orí ilẹ̀ ayé?" 11 A fi aṣọ funfun fún gbogbo wọn; a fún wọn , wọn ó sinmi fún ìgbà díẹ̀ , títí iye àwọn ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ wọn àti arákùnrin wọn a o pa wọn, yóò fi .

12 6.12: Jl 2.31; Ap 2.20. Nígbà ó ṣí èdìdì kẹfà mo i, kíyèsi i, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá kan ṣẹ̀; oòrùn dúdú aṣọ ̀fọ̀ onírun, òṣùpá dàbí ̀jẹ̀; 13 6.13: Isa 34.4.àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run ṣubú sílẹ̀ gẹ́gẹ́ igi ̀pọ̀tọ́ ń rẹ̀ àìgbó èso rẹ̀ dànù, nígbà ̀fúùfù ńlá í. 14 A ̀run kúrò ìwé a , àti olúkúlùkù òkè àti erékùṣù a ṣí kúrò ipò wọn.

15 6.15: Isa 2.10. Àwọn ọba ayé àti àwọn ọlọ́àti àwọn olórí ogun, àti àwọn ọlọ́rọ̀ àti àwọn alágbára, àti olúkúlùkù ẹrú, àti olúkúlùkù òmìnira, fi ara wọn pamọ́ nínú ihò ilẹ̀, àti nínú àpáta orí òkè; 16 6.16: Ho 10.8.wọ́n ń fún àwọn òkè àti àwọn àpáta náà , ", fi pamọ́ kúrò lójú ẹni ó jókòó lórí ìtẹ́, àti kúrò nínú ìbínú ̀dọ́-Àgùntàn náà. 17 6.17: Jl 2.11; Ml 3.2.Nítorí ọjọ́ ńlá ìbínú wọn ; ta ni ó le dúró?"

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-