Publicidade

Apocalipse 7

̀kẹ́ méje ó ẹgbàajì èdìdì ìwé

1 Lẹ́yìn èyí ni mo angẹli mẹ́rin dúró igun mẹ́rẹ̀̀rin ayé, wọ́n di afẹ́fẹ́ mẹ́rẹ̀̀rin ayé , ó ṣe fẹ́ sórí ilẹ̀, tàbí sórí Òkun, tàbí sára igikígi. 2 Mo angẹli mìíràn ó ń ti ìhà ìlà-oòrùn gòkè , ti òun ti èdìdì Ọlọ́run alààyè lọ́wọ́ rẹ. Ó kígbe ohùn rara àwọn angẹli mẹ́rin náà a fi fún un láti pa ayé, àti Òkun, lára, 3 , "ṣe pa ayé, tàbí Òkun, tàbí igi lára, títí àwa ó fi fi èdìdì sàmì àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run wa iwájú wọn." 4 Mo gbọ́ iye àwọn a fi èdìdì sàmì si, àwọn a sàmì jẹ́ ̀kẹ́ méje ó ẹgbàajì (144,000) láti inú gbogbo ̀àwọn ọmọ Israẹli .

5 Láti inú ̀Juda a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Reubeni a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Gadi a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

6 Láti inú ̀Aṣeri a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Naftali a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Manase a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

7 Láti inú ̀Simeoni a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Lefi a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Isakari a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

8 Láti inú ̀Sebuluni, a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Josẹfu a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

Láti inú ̀Benjamini a fi èdìdì sàmì ẹgbàá mẹ́(12,000).

̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn nínú ̀funfun

9 Lẹ́yìn náà, mo ri, kíyèsi i, ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ẹnikẹ́ni , láti inú orílẹ̀-èdè gbogbo, àti ̀, àti ènìyàn, àti láti inú èdè gbogbo , wọn dúró níwájú ìtẹ́, àti níwájú ̀dọ́-Àgùntàn náà, a wọ̀ wọ́n ni aṣọ funfun, imọ̀ ̀pẹ si ń bẹ ni ọwọ́ wọn. 10 Wọ́n kígbe ohùn rara, :

"Ìgbàlà ni ti Ọlọ́run

o jókòó lórí ìtẹ́,

àti ti ̀dọ́-àgùntàn!"

11 Gbogbo àwọn angẹli dúró ìtẹ́ náà , àti àwọn àgbà àti àwọn ̀alààyè mẹ́rin náà , wọn wólẹ̀ wọn si dojúbolẹ̀ níwájú ìtẹ́ náà wọ́n sin Ọlọ́run. 12 pe:

"Àmín!

Ìbùkún, àti ògo,

àti ọgbọ́n, àti ọpẹ́, àti ọlá,

àti agbára àti ipá fún Ọlọ́run wa láé àti láéláé!

Àmín!"

13 ̀kan nínú àwọn àgbà náà si dáhùn, ó bi , "Ta ni àwọn wọ̀nyí a wọ ni aṣọ funfun? Níbo ni wọn ti ?"

14 Mo fún un , "Olúwa mi, ìwọ ni o mọ̀."

Ó fún , "Àwọn wọ̀nyí ni o jáde láti inú ìpọ́njú ńlá, wọ́n fọ aṣọ wọ́n, wọ́n sọ wọ́n di funfun nínú ̀jẹ̀ ̀dọ́-àgùntàn náà. 15 Nítorí náà ni,

"wọn ṣe ń bẹ níwájú ìtẹ́ Ọlọ́run,

wọn ń sìn ín, lọ́sàn àti lóru nínú tẹmpili rẹ̀;

ẹni o jókòó lórí ìtẹ́ náà yóò si síji wọn.

16 Ebi yóò pa wọn mọ́,

bẹ́̀ ni òùngbẹ yóò gbẹ́ wọ́n mọ́;

bẹ́̀ ni oòrùn yóò pa wọn

tàbí oorukóoru kan.

17 Nítorí ̀dọ́-àgùntàn ń bẹ ni àárín ìtẹ́ náà ni yóò máa ṣe olùṣọ́-àgùntàn wọn,

yóò máa ṣe amọ̀wọn ibi orísun omi ìyè.

Ọlọ́run yóò nu omijé gbogbo kúrò ni ojú wọn.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-