Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 7

16 7.16: Isa 49.10; Sm 121.6. Ebi yóò pa wọn mọ́,

bẹ́̀ ni òùngbẹ yóò gbẹ́ wọ́n mọ́;

bẹ́̀ ni oòrùn yóò pa wọn

tàbí oorukóoru kan.

17 7.17: El 34.23; Sm 23.2; Isa 25.8. Nítorí ̀dọ́-àgùntàn ń bẹ ni àárín ìtẹ́ náà ni yóò máa ṣe olùṣọ́-àgùntàn wọn,

yóò máa ṣe amọ̀wọn ibi orísun omi ìyè.

Ọlọ́run yóò nu omijé gbogbo kúrò ni ojú wọn.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também