Pular para o conteúdo
Publicidade

Atos 12

Peteru bọ́ kúrò ̀wọ̀n pẹ̀ìyanu

1 àkókò ìgbà náà ni Herodu ọba nawọ́ rẹ̀ àwọn kan nínú ìjọ, pẹ̀èrò láti pọ́n wọn lójú. 2 Ó fi idà pa Jakọbu arákùnrin Johanu. 3 Nígbà ó èyí dùn mọ́ àwọn Júù nínú, ó nawọ́ Peteru pẹ̀. Ó jẹ́ ìgbà àjọ àìwúkàrà. 4 Nígbà o un, ó fi i sínú túbú, ó fi àwọn ̀ṣọ́ mẹ́rin ti ọmọ-ogun lọ́wọ́ láti máa ṣọ́ . Herodu ń láti un jáde fún àwọn ènìyàn lẹ́yìn ìrékọjá fún ìdájọ́.

5 Nítorí náà wọn fi Peteru pamọ́ sínú túbú; ṣùgbọ́n ìjọ ń fi ìtara gbàdúrà sọ́dọ̀ Ọlọ́run fún un.

6 òru náà gan an ti Herodu ìbá un jáde, Peteru ń sùn láàrín àwọn ọmọ-ogun méjì, a fi ̀wọ̀n méjì é, ̀ṣọ́ ẹnu-ọ̀, wọ́n ń ṣọ́ túbú náà. 7 ó, angẹli Olúwa farahàn, ìmọ́lẹ̀ mọ́ nínú túbú; ó lu Peteru pẹ́pẹ́ lẹ́gbẹ̀́, ó i, ó ni, "Dìde kánkán!" ̀wọ̀n bọ́ sílẹ̀ kúrò ọwọ́ Peteru.

8 Angẹli náà fún un , "Di àmùrè rẹ̀, ó wọ sálúbàtà rẹ!" Peteru ṣe bẹ́̀. Ó fún un , "Da aṣọ rẹ́ bora, ki ó máa tọ̀ lẹ́yìn!" 9 Peteru jáde, ó ń tọ̀ ́ lẹ́yìn; mọ̀ ohun a ṣe láti ọwọ́ angẹli náà jẹ́ òtítọ́, ṣùgbọ́n ó ṣe òun lójú ìran. 10 Nígbà wọ́n kọjá ìṣọ́ èkínní àti èkejì, wọ́n ẹnu-ọ̀ìlẹ̀kùn irin ó lọ ìlú. Ó tìkára rẹ̀ ṣí sílẹ̀ fún wọn: wọ́n jáde, wọ́n ń gba ̀ìgboro kan lọ; lójúkan náà angẹli náà fi í sílẹ̀ lọ.

11 Nígbà ojú Peteru wálẹ̀, ó , "Nígbà yìí ni mo mọ̀ nítòótọ́ , Olúwa rán angẹli rẹ̀, ó gbà mi lọ́wọ́ Herodu àti gbogbo ohun àwọn ènìyàn Júù ń retí!"

12 Nígbà ó, ó lọ ilé Maria ìyá Johanu, àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Marku; níbi àwọn ènìyàn púpọ̀ péjọ , wọn ń gbàdúrà. 13 ó ti kan ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀, ọmọbìnrin kan a n Roda láti dáhùn. 14 Nígbà ó ti mọ ohùn Peteru, ṣí ìlẹ̀kùn nítorí ayọ̀ kún ọkàn rẹ̀ gidigidi, ṣùgbọ́n ó súré wọ ilé, ó sísọ , Peteru dúró ẹnu-ọ̀.

15 Wọ́n fún un , "Ìwọ ń ṣe òmùgọ̀!" Ṣùgbọ́n ó tẹnumọ́ ọn gidigidi bẹ́̀ ni sẹ́. Wọn , "Angẹli rẹ̀ ni!"

16 Ṣùgbọ́n Peteru ń kànkùn síbẹ̀, nígbà wọn ṣí ìlẹ̀kùn, wọ́n i, ẹnu wọ́n. 17 Ṣùgbọ́n ó juwọ́ wọn wọn dákẹ́, ó ròyìn fún wọn Olúwa ti òun jáde kúrò nínú túbú. Ó , "ro èyí fún Jakọbu àti àwọn arákùnrin yòókù!" Ó jáde, ó lọ ibòmíràn.

18 Nígbà ilẹ̀ mọ́, ìrúkèrúdò díẹ̀ kọ́ ni ó láàrín àwọn ọmọ-ogun nípa ohun ó Peteru. 19 Nígbà Herodu a kiri, i, ó wádìí àwọn ̀ṣọ́, ó pàṣẹ , a pa wọ́n.

Ikú Herodu

Herodu sọ̀kalẹ̀ láti Judea lọ Kesarea, ó níbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀. 20 Herodu ń bínú gidigidi àwọn ará Tire àti Sidoni; ṣùgbọ́n wọ́n fi ìmọ̀ ṣọ̀kan sọ́dọ̀ rẹ̀, nígbà wọn ti tu Bilasitu ìwẹ̀ọba lójú, wọn ń bẹ̀bẹ̀ fún àlàáfíà, nítorí ìlú ọba náà ni ìlú wọ́n ti ń gba oúnjẹ.

21 Ni ọjọ́ àfiyèsí kan, Herodu nínú aṣọ ìgúnwà rẹ̀, ni orí ìtẹ́ rẹ̀, ó ń àwọn àjọ ènìyàn sọ̀rọ̀ gbangba. 22 Àwọn ènìyàn , "Ohùn ọlọ́run ni èyí, í í ṣe ti ènìyàn!" 23 Lójúkan náà, nítorí ti Herodu fi ògo fún Ọlọ́run, angẹli Olúwa ú, ó , ìdin jẹ ́.

24 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Ọlọ́run gbilẹ̀, ó i.

A rán Barnaba àti Paulu fún iṣẹ́ ìránṣẹ́

25 Barnaba àti Saulu padà láti Jerusalẹmu, nígbà ti wọ́n parí iṣẹ́ ìránṣẹ́ wọn, wọn Johanu ẹni àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Marku pẹ̀wọn.

Veja também