Publicidade

Atos 16

Timotiu darapọ̀ mọ́ Paulu àti Sila

1 Ó Dabe àti Lysra: kíyèsi i, ọmọ-ẹ̀yìn kan níbẹ̀, a ń Timotiu, ọmọ obìnrin kan í ṣe Júù, ó gbàgbọ́; ṣùgbọ́n Giriki baba rẹ̀. 2 Ẹni a ròhìn rẹ̀ rere lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin ó Lysra àti Ikoniomu. 3 Òun ni Paulu fẹ́ ó òun lọ; ó un, ó kọ ́ ilà, nítorí àwọn Júù ó agbègbè wọ̀nyí, nítorí gbogbo wọn mọ̀ , Giriki ni baba rẹ̀. 4 wọn ti ń la àwọn ìlú lọ, wọ́n ń fi àwọn àṣẹ, a pinnu láti ̀dọ̀ àwọn aposteli àti àwọn alàgbà ó Jerusalẹmu, wọn lọ́wọ́ láti máa pa wọ́n mọ́. 5 Bẹ́̀ ni àwọn ìjọ fẹsẹ̀múlẹ̀ ìgbàgbọ́, wọn ń pọ̀ i iye lójoojúmọ́.

Ìran Paulu nípa arákùnrin Makedonia

6 Wọ́n la agbègbè Frigia , àti Galatia, nítorí ̀Mímọ́ kọ̀ fún wọn láti sọ ̀rọ̀ náà ni Asia. 7 Nígbà wọ́n ̀kánkán Misia, wọ́n gbìyànjú láti lọ Bitinia, ṣùgbọ́n ̀Jesu gbà fún wọn. 8 Nígbà wọ́n kọjá lẹ́bàá Misia, wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ Troasi. 9 Ìran kan si hàn Paulu ni òru, ọkùnrin kan ará Makedonia dúró, ó ń bẹ̀ ́, , "Rékọjá Makedonia, o ràn lọ́wọ́!" 10 Nígbà ó ìran náà, lọ́gán ó múra láti lọ Makedonia, a ka á , Ọlọ́run láti wàásù ìyìnrere fún wọn.

Ìyípadà Lidia Filipi

11 Nítorí náà nígbà àwa ṣíkọ̀ Troasi a ba ̀tààrà lọ Samotrakea, ni ọjọ́ kejì a Neapoli; 12 láti ibẹ̀ àwa lọ si Filipi, í ṣe ìlú Makedonia, olú ìlú ìhà ibẹ̀, ìlú lábẹ́ Romu, àwa jókòó ìlú yìí fún ọjọ́ mélòó kan.

13 Lọ́jọ́ ìsinmi, àwa jáde lọ ̀yìn odi ìlú náà, lẹ́bàá odò kan, níbi a ibi àdúrà ; àwa jókòó, a àwọn obìnrin o péjọ sọ̀rọ̀. 14 Àti obìnrin kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Lidia, elése àlùkò, ará ìlú Tiatira, ẹni ó sin Ọlọ́run, ó gbọ́ ̀rọ̀ wa, ọkàn ẹni Olúwa ṣí láti fetísí ohun a ẹnu Paulu sọ. 15 Nígbà a bamitiisi rẹ̀, àti àwọn ara ilé rẹ̀, ó bẹ̀ , , "̀yin ni olóòtítọ́ Olúwa, si ilé mi, wọ̀ níbẹ̀!" O rọ̀ .

Paulu àti Sila nínú túbú

16 àwa n lọ ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan o ̀àfọ̀ṣẹ, pàdé wa, ẹni ó fi àfọ̀ṣẹ èrè púpọ̀ fún àwọn ̀rẹ̀. 17 Òun náà ni ó ń tọ Paulu àti àwa lẹ́hìn, ó ń kígbe, , "Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ni ìránṣẹ́ Ọlọ́run ̀gá-ògo, ń kéde ̀ìgbàlà fún yin!" 18 Ó ń ṣe èyí lọ́jọ́ púpọ̀, ṣùgbọ́n nígbà inú Paulu bàjẹ́, ó yípadà, ó fún ̀náà , "Mo pàṣẹ fún orúkọ Jesu Kristi o jáde kúrò lára rẹ̀!" Ó jáde ni wákàtí kan náà.

19 Nígbà àwọn ̀rẹ̀ i , ìgbẹ́kẹ̀èrè wọn pin, wọ́n Paulu àti Sila, wọn wọ́ wọn lọ ọjà tọ àwọn aláṣẹ lọ. 20 Nígbà wọ́n wọn tọ àwọn onídàájọ́ lọ, wọ́n , "Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí í ṣe Júù, wọ́n ń yọ ìlú wa lẹ́nu jọjọ, 21 wọ́n ń kọ́ni àṣà yẹ fún wa, àwa ẹni í ṣe ara Romu, láti gbà àti láti tẹ̀."

22 ̀pọ̀ ènìyàn jùmọ̀ dìde Paulu àti Sila. Àwọn olórí wọ́n aṣọ ya, wọ́n pàṣẹ , ki a fi ̀gọ̀ wọ́n. 23 Nígbà wọ́n wọ́n púpọ̀, wọ́n sọ wọ́n sínú túbú, wọ́n kìlọ̀ fún onítúbú ó pa wọ́n mọ́ dáradára. 24 Nígbà ó gbọ́ irú ìkìlọ̀ bẹ́̀, ó sọ̀ wọ́n sínú túbú inú lọ́hùn, ó kan àbà mọ wọ́n lẹ́sẹ̀.

25 Ṣùgbọ́n láàrín ̀gànjọ́ Paulu àti Sila ń gbàdúrà, wọ́n ń kọrin ìyìn si Ọlọ́run, àwọn ara túbú ń tẹ́wọn. 26 Lójijì ilẹ̀ mímì ńlá mi, bẹ́̀ ìpìlẹ̀ ilé túbú tìtì: lọ́gán, gbogbo ìlẹ̀kùn ṣí, ìdè gbogbo wọn sílẹ̀. 27 Nígbà onítúbú si tají, o ri , àwọn ìlẹ̀kùn túbú ṣí sílẹ̀, ó fa idà rẹ̀ yọ, ó fẹ́ pa ara rẹ̀, ó ṣe àwọn ara túbú ti sálọ. 28 Ṣùgbọ́n Paulu gbé ohun rẹ̀ sókè, , "ṣe pa ara rẹ lára: nítorí gbogbo wa ń bẹ níhìn-ín yìí!"

29 Nígbà ó béèrè iná, ó bẹ́ wọ inú ilé, ó ń wárìrì, ó wólẹ̀ níwájú Paulu àti Sila. 30 Ó wọn jáde, ó , "Alàgbà, kín ni ki èmi ṣe ki n ?"

31 Wọ́n fún un , "Gbá Jesu Kristi Olúwa gbọ́, a ó gbà ́ , ìwọ àti àwọn ará ilé rẹ pẹ̀." 32 Wọ́n sọ ̀rọ̀ Olúwa fún un, àti fún gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀. 33 Ó wọn wákàtí náà lóru, ó wẹ ọgbẹ́ wọn; a bamitiisi rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ lójúkan náà. 34 Ó wọn ilé rẹ̀, ó gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú wọn, ó yọ̀ gidigidi pẹ̀gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, nítorí ó gba Ọlọ́run gbọ́.

35 Ṣùgbọ́n nígbà ilẹ̀ mọ́, àwọn onídàájọ́ rán àwọn ọlọ́pàá , "àwọn ènìyàn náà sílẹ̀." 36 Onítúbú sọ ̀rọ̀ náà fún Paulu, , "Àwọn onídàájọ́ ránṣẹ́ á da ìwọ àti Sila sílẹ̀. Ǹjẹ́ nísinsin yìí jáde máa lọ àlàáfíà."

37 Ṣùgbọ́n Paulu fún wọn , "Wọ́n ni gbangba, wọ́n sọ sínú túbú ni àìjẹ̀bi, àwa ẹni ì ṣe ara Romu. Ṣe nísinsin yìí wọ́n fẹ́ jáde níkọ̀kọ̀? Rara! Ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn wa jáde!"

38 Àwọn ọlọ́pàá sọ ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn onídàájọ́: ̀wọ́n, nígbà wọ́n gbọ́ ará Romu ni Paulu àti Sila. 39 Wọ́n , wọ́n ṣìpẹ̀ lọ́dọ̀ wọ́n, wọn wọn jáde, wọ́n bẹ̀ wọ́n , ki wọn jáde kúrò ni ìlú náà. 40 Paulu àti Sila jáde nínú túbú, wọ́n wọ ilé Lidia lọ, nígbà wọn àwọn arákùnrin, wọ́n wọ́n nínú, wọn jáde kúrò.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-