Publicidade

Atos 18

Kọrinti

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Paulu jáde kúrò ni Ateni lọ Kọrinti. 2 Ó Júù kan a ń Akuila, a ni Pọntu, ó ti Itali lọ́́lọ́́, pẹ̀Priskilla aya rẹ̀; nítorí Kilaudiu pàṣẹ , gbogbo àwọn Júù jáde kúrò Romu. Ó tọ̀ wọ́n lọ láti wọn. 3 Nítorí òun náà jẹ́ oníṣẹ̀-ọwọ́ kan náà, ó wọn jókòó, ó ń ṣiṣẹ́: nítorí àgọ́ pípa ni iṣẹ́ ọwọ́ wọn. 4 Ó ń fi ̀rọ̀ ̀rọ̀ pẹ̀wọn nínú Sinagọgu lọ́jọjọ́ ìsinmi, ó ń àwọn Júù àti àwọn Giriki lọ́kàn padà.

5 Nígbà Sila àti Timotiu Makedonia , ̀rọ̀ náà Paulu lára, ó ń fihàn fún àwọn Júù , Jesu ni Kristi náà. 6 Nígbà wọ́n sàtakò rẹ̀, wọ́n sọ̀rọ̀-òdì, ó gbọ́n aṣọ rẹ̀, ó fún wọn , "̀jẹ̀ yin ń bẹ lórí ara yin; ọrùn mi mọ́: láti ìsinsin yìí lọ, èmi yóò tọ àwọn aláìkọlà lọ."

7 Ó lọ kúrò níbẹ̀, ó wọ ilé ọkùnrin kan a ń Titu Justu, ẹni o ń sin Ọlọ́run; ilé rẹ̀ lẹ́gbẹ̀ Sinagọgu tímọ́tímọ́. 8 Krisipu, olórí Sinagọgu, gba Olúwa gbọ́ pẹ̀gbogbo ilé rẹ̀, àti ̀pọ̀ nínú àwọn ara Kọrinti, nígbà wọ́n gbọ́, wọ́n gbàgbọ́, a bamitiisi wọn.

9 Olúwa sọ fún Paulu lóru ni ojúran , "bẹ̀, ṣá máa sọ, ṣe pa ẹnu rẹ̀ mọ́. 10 Nítorí èmí pẹ̀rẹ, ẹni yóò dìde láti pa lára: nítorí mo ènìyàn púpọ̀ ni ìlú yìí." 11 Ó jókòó níbẹ̀ ọdún kan àti oṣù mẹ́, ó ń kọ́ni ̀rọ̀ Ọlọ́run láàrín wọn.

12 Nígbà Gallioni jẹ baálẹ̀ Akaia, àwọn Júù fi ìfìmọ̀ṣọ̀kan dìde Paulu wọn un síwájú ìtẹ́ ìdájọ́. 13 Wọ́n , "Ọkùnrin yìí ń àwọn ènìyàn lọ́kàn padà, láti máa sin Ọlọ́run lòdì òfin."

14 Nígbà Paulu ń fẹ́ dáhùn, Gallioni fún àwọn Júù , "Ìbá ṣe ̀ràn búburú tàbí jàgídíjàgan kan ni, èmi ìbá gbè yín, ̀yin Júù, 15 Ṣùgbọ́n ó ti ṣe ̀ràn nípa ̀rọ̀ àti orúkọ, àti ti òfin yín ni, ki ̀yin bojútó o fúnra yín; nítorí èmi fẹ́ ṣe onídàájọ́ nǹkan báwọ̀nyí." 16 Ó wọn kúrò ibi ìtẹ́ ìdájọ́. 17 Gbogbo àwọn Giriki Sostene, olórí Sinagọgu, wọ́n ú níwájú ìtẹ́ ìdájọ́. Gallioni bìkítà fún nǹkan wọ̀nyí.

Priskilla, Akuila àti Apollo

18 Paulu dúró i níbẹ̀ lọ́jọ́ púpọ̀, nígbà ó dágbére fún àwọn arákùnrin, ó ọkọ̀ ojú omi lọ si Siria, àti Priskilla àti Akuila pẹ̀rẹ̀; ó orí rẹ̀ ni Kenkerea, nítorí ó ti jẹ́ ̀jẹ́. 19 Ó sọ̀kalẹ̀ Efesu, ó fi wọ́n sílẹ̀ níbẹ̀, ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ wọ inú Sinagọgu lọ, ó àwọn Júù fi ̀rọ̀ ̀rọ̀. 20 Nígbà wọ́n bẹ̀ ́ , ó àwọn jókòó díẹ̀ i, ó kọ̀. 21 Ṣùgbọ́n ó dágbére fún wọn, ó , "Èmi ó tún padà tọ̀ yín , Ọlọ́run fẹ́." Ó lọ kúrò láti Efesu. 22 Nígbà ó gúnlẹ̀ ni Kesarea, ó gòkè lọ si Jerusalẹmu láti ìjọ, lẹ́yìn náà ó sọ̀kalẹ̀ lọ Antioku.

23 Nígbà ó gbé ọjọ́ díẹ̀ níbẹ̀, ó n lọ, láti káàkiri ni agbègbè Galatia àti Frigia, o ń mu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn lọ́kàn le.

24 Júù kan a ń ni Apollo, a ni Alekisandiria, ó Efesu. Ó ̀bùn ̀rọ̀ sísọ, ó mọ ìwé mímọ́ púpọ̀. 25 Ọkùnrin yìí ni a kọ́ ̀Olúwa; ó ṣe ẹni ó ìtara ̀, ó ń sọ̀rọ̀ ó ń kọ́ni àwọn ohun i ṣe ti Jesu dáradára; kìkì bamitiisi Johanu ó mọ̀. 26 Ó bẹ̀rẹ̀ fi ìgboyà sọ̀rọ̀ ni Sinagọgu. Nígbà Akuila àti Priskilla gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n un sọ́dọ̀, wọ́n túbọ̀ sọ ̀Ọlọ́run fún un dájúdájú.

27 Nígbà ó ń fẹ́ kọjá lọ Akaia, àwọn arákùnrin gbà á ìyànjú, wọ́n kọ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wọ́n gbà á, nígbà ó , ó ràn àwọn ó gbàgbọ́ nípasẹ̀ oore-ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ púpọ̀. 28 Nítorí o sọ àsọyé fún àwọn Júù gbangba, ó ń fi í hàn nínú ìwé mímọ́ , Jesu ni Kristi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-