Publicidade

Atos 24

Ìpèlẹ́jọ́ níwájú Feliksi

1 Lẹ́yìn ọjọ́ márùn-ún Anania olórí àlùfáà náà sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀àwọn alàgbà àti ẹnìkan, Tertulu agbẹjọ́, ẹni ó sọ̀rọ̀ ẹjọ́ Paulu fún baálẹ̀. 2 Nígbà a Paulu jáde, Tertulu gbé ẹjọ́ rẹ̀ kalẹ̀ níwájú Feliksi ó , "Àwa ti àlàáfíà abẹ́ ìjọba rẹ láti ìgbà pípẹ́ , àti ìfojúsùn rẹ ti àyípadà rere orílẹ̀-èdè yìí. 3 ibi gbogbo àti ̀gbogbo, Feliksi ọlọ́jùlọ, àwa ń tẹ́wọ́gbà á pẹ̀ọpẹ́ gbogbo. 4 Ṣùgbọ́n èmi ba á dúró pẹ́ títí, mo bẹ̀ ́ o fi ìyọ́rẹ gbọ́ ̀rọ̀ díẹ̀ lẹ́nu wa.

5 "Nítorí àwa ọkùnrin yìí, ó jẹ́ oníjàngbàn ènìyàn, ẹni ó ń rúkèrúdò sílẹ̀ láàrín gbogbo àwọn Júù ó gbogbo ayé. Òun ni aṣáájú búburú kan nínú ̀àwọn Nasarene, 6 ẹni ó gbìyànjú láti ba tẹmpili jẹ́. 8 Nígbà ìwọ fúnra rẹ̀ wádìí ̀rọ̀ fínní fínní lẹ́nu rẹ̀, ìwọ ó òye òtítọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí àwa fi ̀sùn rẹ̀ kàn án."

9 Àwọn Júù pẹ̀fi ohùn i , òtítọ́ bẹ́̀ ni nǹkan wọ̀nyí .

10 Nígbà baálẹ̀ ṣẹ́wọ́ i ó sọ̀rọ̀, Paulu dáhùn pe, "mo mọ̀ láti ọdún mélòó yìí , ìwọ ṣe onídàájọ́ orílẹ̀-èdè yìí, nítorí náà mo fi tayọ̀tayọ̀ ẹnu mi. 11 Ìwọ pẹ̀òye rẹ̀ , ìjejìlá ni mo lọ Jerusalẹmu láti lọ jọ́sìn. 12 Bẹ́̀ ni àwọn olùfisùn mi mi ń máa ẹnikẹ́ni jiyàn nínú tẹmpili, bẹ́̀ ni èmi ru àwọn ènìyàn sókè nínú Sinagọgu tàbí ibikíbi nínú ìlú. 13 Bẹ́̀ ni wọ́n fi ìdí ̀sùn múlẹ̀ níwájú rẹ, èyí wọn fi sùn nísinsin yìí. 14 Ṣùgbọ́n, èmí jẹ́wọ́ fún , èmi ń sin Ọlọ́run àwọn baba wa gẹ́gẹ́ èmi ti ń tẹ̀̀wọ́n ń ni ìyapa ìsìn. Èmi ń gbá gbogbo nǹkan ti a kọ sínú ìwé òfin gbọ́, àti a kọ sínú ìwé àwọn wòlíì, 15 mo ìrètí kan náà nínú Ọlọ́run gẹ́gẹ́ àwọn tìkára wọn jẹ́wọ́ pẹ̀, àjíǹde òkú ń bọ̀, àti olóòtítọ́, àti aláìṣòótọ́. 16 Nínú èyí ni èmi ti ń gbìyànjú láti ̀ọkàn lẹ́sẹ̀ Ọlọ́run, àti ènìyàn nígbà gbogbo.

17 "Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọdún púpọ̀, mo Jerusalẹmu láti mu ̀bùn fún àwọn ènìyàn mi fún aláìní àti láti fi ọrẹ lélẹ̀. 18 Nínú ṣíṣe nǹkan wọ̀nyí, wọ́n nínú ìyẹ̀tẹmpili, mo ti ń parí ètò ìwẹ̀, bẹ́̀ ni í ṣe àárín àwùjọ ènìyàn, tàbí pẹ̀ariwo. 19 Ṣùgbọ́n àwọn Júù kan láti ẹkùn Asia níbẹ̀, àwọn ìbá níhìn-ín yìí níwájú rẹ, wọn mi nírọ́, wọ́n ohunkóhun mi. 20 ṣe bẹ́̀, jẹ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí tìkára wọn sọ iṣẹ́ búburú wọ́n lọ́wọ́ mi, nígbà mo dúró níwájú àjọ ìgbìmọ̀. 21 ṣe gbólóhùn kan yìí, mo kégbe rẹ̀ síta nígbà mo dúró láàrín wọn: Èyí ni tìtorí àjíǹde òkú ni a ṣe ba mi wíjọ́ lọ́dọ̀ yín ni yìí!’ "

22 Nígbà Feliksi gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, òye à ye é àyétán nípa ̀náà; ó wọn , ó , "Nígbà Lisia olórí ogun sọ̀kalẹ̀ , èmi ó wádìí ̀ràn yín dájú." 23 Ó pàṣẹ fún balógun ̀run kan ó máa ṣe ìtọ́Paulu, ó fún un ààyè, àti ó ṣe àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ lẹ́kun láti máa ṣe ìránṣẹ́ fún un.

24 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan Feliksi pẹ̀Drusilla ìyàwó rẹ̀ , obìnrin í ṣe Júù. Ó ránṣẹ́ Paulu, ó gbọ́ ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ̀ nípa ìgbàgbọ́ nínú Kristi Jesu. 25 Paulu ń sọ àsọyé nípa òdodo àti àìrékọjá àti ìdájọ́ ń bọ̀, ̀ba Feliksi, ó dáhùn , "Èyí o sọ ! Máa lọ nísinsin yìí . Nígbà mo àkókò ó wọ̀, èmi ó ránṣẹ́ ́." 26 àkókò yìí kan náà, ó ń retí pẹ̀Paulu yóò owó ̀yìn fún òun, òun ba à a sílẹ̀, nítorí náà a máa ránṣẹ́ í nígbàkígbà, a máa a sọ̀rọ̀.

27 Lẹ́yìn ọdún méjì, Porkiu Festu rọ́Feliksi, Feliksi ń fẹ́ ṣe ojúrere fún àwọn Júù, ó fi Paulu sílẹ̀ nínú túbú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-