Publicidade

Atos 3

Peteru oníbárà arọ láradà

1 ọjọ́ kan Peteru àti Johanu jùmọ̀ ń gòkè lọ tẹmpili wákàtí àdúrà; í ṣe wákàtí mẹ́ta ̀sán. 2 Wọn gbé ọkùnrin kan ti ó yarọ láti inú ìyá rẹ̀ , wọ́n máa ń gbé kalẹ̀ lójoojúmọ́ ẹnu-ọ̀tẹmpili ti a ń ni Dáradára, láti máa ṣagbe lọ́wọ́ àwọn ń wọ inú tẹmpili lọ. 3 Nígbà ó Peteru àti Johanu wọn fẹ́ wọ inú tẹmpili, ó ṣagbe. 4 Peteru tẹjúmọ́ ọn, pẹ̀Johanu, ó "!" 5 Ó fiyèsí wọn, ó ń retí láti nǹkan láti gbà lọ́wọ́ wọn.

6 Peteru , "Wúrà àti fàdákà èmi , ṣùgbọ́n ohun mo èyí náà ni mo fi fún . orúkọ Jesu Kristi ti Nasareti, dìde o máa rìn." 7 Ó á lọ́wọ́ ̀tún, ó gbé dìde; lójúkan náà ẹsẹ̀ rẹ̀ àti egungun kókósẹ̀ rẹ̀ mókun. 8 Ó ń sókè, ó dúró, ó bẹ̀rẹ̀ rìn, ó wọn wọ inú tẹmpili lọ, ó ń rìn, ó ń , ó yín Ọlọ́run. 9 Gbogbo ènìyàn i, ó ń rìn, ó yin Ọlọ́run, 10 Wọn mọ̀ òun ni ó ti jókòó ń ṣagbe ẹnu-ọ̀Dáradára ti tẹmpili náà; , ṣe wọn, ẹnu wọn gidigidi ohun ó ṣe lára rẹ̀.

Peteru sọ̀rọ̀ àwọn olùwòran

11 arọ ti a láradá ti di Peteru àti Johanu , gbogbo ènìyàn jùmọ̀ súre tọ̀ wọ́n lọ ni ìloro ti a ń ti Solomoni, pẹ̀ìyàlẹ́nu ńlá. 12 Nígbà Peteru i, ó dáhùn, ó fún àwọn ènìyàn , "̀yin ènìyàn Israẹli, èéṣe háà fi ń ṣe yín èyí? Tàbí èéṣe ti ̀yin fi tẹjúmọ́ wa, ẹni agbára tàbí ìwà mímọ́ wa ni àwa fi ṣe é ti ọkùnrin yìí fi ń rìn? 13 Ọlọ́run Abrahamu, àti Isaaki, àti Jakọbu, Ọlọ́run àwọn baba wa, òun ni ó ti yin Jesu ìránṣẹ́ rẹ̀ lógo; ẹni ̀yin ti fi wọn lọ́wọ́, ̀yin sẹ́ níwájú Pilatu, nígbà ó ti pinnu rẹ̀ láti a sílẹ̀. 14 Ṣùgbọ́n ̀yin ṣẹ́ Ẹni Mímọ́ àti Olóòótọ́ náà, ̀yin béèrè a fi apànìyàn fún un yín. 15 ̀yin pa ìpilẹ̀ṣẹ̀ ìyè, ẹni Ọlọ́run ti dìde kúrò nínú òkú; ẹlẹ́rìí èyí ti àwa jẹ́. 16 Nípa ìgbàgbọ́ nínú orúkọ Jesu, òun ni ó ọkùnrin yìí láradá, ẹni ̀yin , mọ̀. Orúkọ Jesu àti ìgbàgbọ́ ó nípa rẹ̀ ni ó fún un ìlera pípé ṣáṣá yìí ni ojú gbogbo yín.

17 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo mọ̀ nípa àìmọ̀ ni ̀yin fi ṣe é, gẹ́gẹ́ àwọn olórí yín pẹ̀ti ṣe. 18 Ṣùgbọ́n báyìí ni Ọlọ́run ti ṣe ìmúṣẹ àwọn ohun ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu gbogbo àwọn wòlíì , Kristi rẹ̀ yóò jìyà. 19 Nítorí náà ronúpìwàdà, yípadà Ọlọ́run, a pa ̀ṣẹ̀ yín rẹ́, àkókò ìtura a ti ̀dọ̀ Olúwa , 20 àti ó ba à rán Kristi a ti yàn fún yín tẹlẹ̀: àní Jesu. 21 Ẹni ̀run ṣàìmá gbà títí di ìgbà ìmúpadà ohun gbogbo, Ọlọ́run ti sọ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ wọn ti ń bẹ nígbà ayé ti ṣẹ̀. 22 Mose , Olúwa Ọlọ́run yín yóò gbé wòlíì kan dìde fún yín nínú àwọn arákùnrin yín, èmi; òun ni ̀yin yóò máa gbọ́ tirẹ̀ ohun gbogbo yóò máa sọ fún un yín. 23 Yóò ṣe, olúkúlùkù ọkàn ti gbọ́ ti wòlíì náà, òun ni a ó parun pátápátá kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.’

24 "Àní, gbogbo àwọn wòlíì láti Samuẹli , àti àwọn ó tẹ̀e, iye àwọn ó ti sọ̀rọ̀, wọn sọ ti ọjọ́ wọ̀nyí pẹ̀. 25 ̀yin ni ọmọ àwọn wòlíì, àti ti májẹ̀Ọlọ́run ti àwọn baba yín nígbà ó fún Abrahamu , Láti ipasẹ̀ irú àwọn ọmọ rẹ̀ ni a ó ti bùkún fún gbogbo ìdílé ayé.26 Nígbà ti Ọlọ́run Jesu Ọmọ rẹ̀ dìde, ó kọ́ rán an i yín láti bùkún fún un yín, nípa yíyí olúkúlùkù yín padà kúrò nínú ìwà búburú rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-