Publicidade

Atos 5

Anania àti Safira

1 Ṣùgbọ́n ọkùnrin kan ti a ń ni Anania, pẹ̀Safira aya rẹ̀, ta ilẹ̀ ìní kan. 2 Nípa ìmọ̀ aya rẹ̀ ó yan apá kan pamọ́ nínú owó náà, ó apá kan rẹ̀ , ó fi í lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ àwọn aposteli.

3 Ṣùgbọ́n Peteru , "Anania, èéṣe ti Satani fi kún ọkàn rẹ láti ṣèké ̀Mímọ́, ìwọ fi yan apá kan pamọ́ nínú owó ilẹ̀ náà? 4 Nígbà ó níbẹ̀ tìrẹ kọ́ í ṣe? Nígbà a ta á tan, ha ìkáwọ́ rẹ̀? Èéha ti ṣe ìwọ fi nǹkan yìí lọ́kàn rẹ? Ènìyàn kọ́ ni ìwọ ṣèké ṣe Ọlọ́run?"

5 Nígbà Anania gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó ṣubú lulẹ̀, ó , ̀ńlá ba gbogbo àwọn ó gbọ́. 6 Àwọn ̀dọ́mọkùnrin dìde, wọ́n í, wọn gbé è jáde, wọn sin ín.

7 Ó ìwọ̀n wákàtí mẹ́ta, aya rẹ̀ láìmọ̀ ohun ó ti ṣẹlẹ̀, ó wọlé. 8 Peteru béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "fún mi, ṣé iye yìí ni ìwọ àti Anania gbà lórí ilẹ̀?"

Ó , "Bẹ́̀ ni, iye rẹ̀ náà ni."

9 Peteru fún un , "Èéṣe ti ̀yin fohùn ṣọ̀kan láti dán ̀Olúwa ? ó, ẹsẹ̀ àwọn ó sìnkú ọkọ rẹ ń bẹ ẹnu-ọ̀, wọn ó gbe ìwọ náà jáde."

10 Lójúkan náà ó ṣubú lulẹ̀ lẹ́sẹ̀ rẹ̀, ó ; àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọlé wọ́n a òkú, wọ́n gbé e jáde, wọ́n sín in lẹ́bàá ọkọ rẹ̀. 11 ̀ńlá gbogbo ìjọ àti gbogbo àwọn ó gbọ́ nǹkan wọ̀nyí.

Àwọn aposteli wo ̀pọ̀ sàn

12 A ti ọwọ́ àwọn aposteli ṣe iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu púpọ̀ láàrín àwọn ènìyàn. Gbogbo wọn fi ọkàn kan ìloro Solomoni. 13 nínú àwọn ìyókù ó jẹ́ gbìyànjú láti darapọ̀ mọ́ wọn, ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ènìyàn ń fi ̀wọ̀ gíga fún wọn. 14 Ṣùgbọ́n síbẹ̀síbẹ̀, a ń yan àwọn ọkùnrin àti àwọn obìnrin ó gba Olúwa gbọ́ kún iye wọn i. 15 bẹ́̀ wọn ń gbé àwọn abirùn jáde òpópónà, wọn ń tẹ́ wọn orí ibùsùn àti àkéte òjìji Peteru ba à le gba orí ẹlòmíràn nínú wọn ó ti ń kọjá lọ. 16 ̀pọ̀ ènìyàn ara wọn jọ láti àwọn ìlú ó Jerusalẹmu , wọn ń àwọn abirùn àti àwọn ara kan fún ̀àìmọ́; a mu olúkúlùkù wọn ara .

Wọ́n ṣe inúnibíni àwọn aposteli

17 Nígbà náà ni ̀owú gbígbóná gbé olórí àlùfáà àti gbogbo àwọn wọn lọ́dọ̀ rẹ̀ ì ṣe ̀àwọn Sadusi wọ̀. 18 Wọ́n nawọ́ àwọn aposteli wọn fi wọ́n sínú túbú. 19 Ṣùgbọ́n òru, angẹli Olúwa ṣí ìlẹ̀kùn túbú; ó wọn jáde. 20 Ó "lọ dúró nínú tẹmpili máa ṣọ́ ̀rọ̀ ìyè yìí ̀kúnrẹ́rẹ́ fún àwọn ènìyàn."

21 Nígbà wọ́n gbọ́ èyí, wọ́n wọ tẹmpili lọ kùtùkùtù, wọ́n ń kọ́ni.

Nígbà olórí àlùfáà àti àwọn ti ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ , wọn àpéjọ ìgbìmọ̀, àti gbogbo àwọn àgbàgbà àwọn ọmọ Israẹli, wọn ránṣẹ́ ilé túbú láti àwọn aposteli . 22 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn olùṣọ́ ibẹ̀ wọn wọn nínú túbú, wọn padà , wọn sísọ fún wọn , 23 "Àwa ilé túbú ni títí pinpin, àti àwọn olùṣọ́ dúró lóde níwájú ìlẹ̀kùn; ṣùgbọ́n nígbà àwa ṣí ìlẹ̀kùn, àwa ẹnìkan nínú túbú." 24 Nígbà olórí ̀ṣọ́ tẹmpili àti àwọn olórí àlùfáà gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n dààmú nítorí wọn mọ ibi ̀rọ̀ yìí yóò yọrí .

25 Nígbà náà ni ẹnìkan , ó fún wọn , "ó, àwọn ọkùnrin ̀yin fi sínú túbú tẹmpili, wọn dúró wọ́n ń kọ́ àwọn ènìyàn." 26 Nígbà náà ni olórí ̀ṣọ́ lọ pẹ̀àwọn olùṣọ́, ó àwọn aposteli . Wọn fi ipá wọn, nítorí wọn bẹ̀àwọn ènìyàn a ba à sọ wọ́n òkúta.

27 Nígbà wọn àwọn aposteli , wọn wọn dúró níwájú àjọ ìgbìmọ̀; olórí àlùfáà bi wọ́n léèrè. 28 Ó , "Àwa ha ti kìlọ̀ fún un yín gidigidi , ṣe fi orúkọ yìí kọ́ni, síbẹ̀ ̀yin ti fi ìkọ́ni yín kún Jerusalẹmu, ń pète àti ̀bi ̀jẹ̀ ọkùnrin yìí orí ."

29 Ṣùgbọ́n Peteru àti àwọn aposteli dáhùn, wọ́n , "Àwa gbọdọ̀ gbọ́ Ọlọ́run ju ti ènìyàn lọ! 30 Ọlọ́run àwọn baba wa Jesu dìde kúrò ipò òkú, ẹni ̀yin pa nípa gbígbékọ́ orí igi. 31 Òun ni Ọlọ́run fi ọwọ́ ̀tún rẹ̀ gbé gẹ́gẹ́ Ọmọ-aládé àti Olùgbàlà láti fi ìrònúpìwàdà àti ìdáríjì ̀ṣẹ̀ fún Israẹli. 32 Àwa ni ẹlẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí, àti gẹ́gẹ́ ̀Mímọ́ ti ṣe ẹlẹ́rìí pẹ̀, Ọlọ́run fi fún àwọn ó gbà á gbọ́."

33 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n gbọ́ èyí, ọkàn wọn gbọgbẹ́ inú, wọ́n gbèrò láti pa wọ́n. 34 Ṣùgbọ́n ̀kan nínú àjọ ìgbìmọ̀, a ń ni Gamalieli, Farisi àti amòfin, ó ìyìn gidigidi lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn, ó dìde dúró, ó ni a àwọn aposteli sẹ́yìn díẹ̀. 35 Ó fún wọn "̀yin ènìyàn Israẹli, kíyèsi ara yín lóhùn ̀yin ń pète láti ṣe àwọn ọkùnrin wọ̀nyí. 36 Nítorí ṣáájú ọjọ́ wọ̀nyí ni Teuda dìde, ó ń , ẹni ńlá kan òun; ẹni ìwọ̀n irinwó (400) ọkùnrin dara wọn pọ̀ mọ́; ṣùgbọ́n a pa á; àti gbogbo iye àwọn ó gba tirẹ̀ túká, wọn di asán. 37 Lẹ́yìn ọkùnrin yìí ni Judasi ti Galili dìde ni àkókò kíka àwọn ènìyàn, ó ni ẹni púpọ̀ lẹ́yìn rẹ̀; òun pẹ̀ṣègbé; àti gbogbo iye àwọn ó gba tirẹ̀ ni a fọ́nká. 38 Ǹjẹ́ èmi fún un yín nísinsin yìí, ṣọ́ra fún àwọn ọkùnrin wọ̀nyí, fi wọn sílẹ̀, nítorí ìmọ̀ tàbí iṣẹ́ yìí jẹ́ ti ènìyàn, a ó í ṣubú. 39 Ṣùgbọ́n ti Ọlọ́run , ̀yin yóò í ṣubú; ó ba à jẹ́ , a yín ẹni ń Ọlọ́run ."

40 Wọ́n gbà ìmọ̀ràn rẹ̀. Wọn pe àwọn aposteli wọlé, wọ́n si wọ́n. Wọn kìlọ̀ fún wọn wọn ṣe sọ̀rọ̀ ni orúkọ Jesu mọ́, wọ́n jọ̀wọ́ wọn sílẹ̀ lọ.

41 Nítorí náà wọn lọ kúrò níwájú àjọ ìgbìmọ̀; wọn ń yọ̀ nítorí a wọ́n yẹ láti jìyà nítorí orúkọ rẹ̀. 42 ojoojúmọ́ nínú tẹmpili àti ni ojúlé ojúlé, wọn dẹ́kun kíkọ́ni àti láti wàásù ìyìnrere náà Jesu ni Kristi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-