Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìṣe àwọn Aposteli 7

44 7.44: Ek 25.9,40. "Àwọn baba wa àgọ́ ̀pẹ̀wọn ijù. Èyí a ṣe gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ó ba Mose sọ̀rọ̀ ó ṣe é, gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ ó ti . 45 7.45: Jo 3.14-17; De 32.49.Ti àwọn baba wa ó tẹ̀wọn Joṣua ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, Ọlọ́run jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí àkókò Dafidi. 46 7.46: 2Sa 7.8-16; Sm 132.1-5.Ẹni ó ojúrere níwájú Ọlọ́run, ó tọrọ láti ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu. 47 7.47: 1Ọb 6.Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.

48 "Ṣùgbọ́n ̀gá-ògo í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ wòlíì ti :

49 7.49-50: Isa 66.1-2. " ̀run ni ìtẹ́ mi,

ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.

Irú ilé kín ̀yin yóò kọ́ fún mi?

ni Olúwa .

Tàbí níbo ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi mi?

50 Ọwọ́ mi ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também