Publicidade

Atos 8

1 Saulu níbẹ̀, ó fi àṣẹ ikú rẹ̀.

Wọ́n ṣe inúnibíni ìjọ, wọ́n túká

àkókò náà, inúnibíni ńlá kan dìde ìjọ ó ni Jerusalẹmu, gbogbo wọn túká káàkiri agbègbè Judea àti Samaria, àyàfi àwọn aposteli. 2 Àwọn ènìyàn olùfọkànsìn kan gbé òkú Stefanu lọ sin, wọ́n pohùnréré ẹkún kíkan sórí rẹ̀. 3 Ṣùgbọ́n Saulu bẹ̀rẹ̀ da ìjọ ènìyàn Ọlọ́run . Ó ń wọ ilé ilé, ó ń àwọn ọkùnrin àti obìnrin, ó ń fi wọn sínú túbú.

Filipi Samaria

4 Àwọn wọ́n túká lọ ibi gbogbo ń wàásù ̀rọ̀ náà. 5 Filipi sọ̀kalẹ̀ lọ ìlú Samaria, ó ń wàásù Kristi fún wọn. 6 Nígbà ìjọ àwọn ènìyàn gbọ́, wọn iṣẹ́ àmì Filipi ń ṣe, gbogbo wọn fi ọkàn kan fiyèsí ohun ó ń sọ. 7 Nítorí àwọn ̀àìmọ́ ń kígbe sókè wọ́n ti ń jáde kúrò lára àwọn ènìyàn, ̀pọ̀ àwọn arọ àti amúnkùn ún ni ó gba ìmúláradá. 8 Ayọ̀ púpọ̀ ni ìlú náà.

Simoni onídán

9 Ṣùgbọ́n ọkùnrin kan , a ń Simoni, ó ti máa ń pa idán ìlú náà, ó ẹnu ya àwọn ará Samaria. Ó máa ń fọ́nnu ènìyàn ńlá kan ni òun. 10 Ẹni gbogbo èwe àti àgbà fiyèsí wọ́n ń bu ọlá fún , "Ọkùnrin yìí agbára Ọlọ́run ti ń jẹ́ ńlá." 11 Wọ́n bu ọlá fún un, nítorí ọjọ́ pípẹ́ ni ó ti ń pa idán fún ìyàlẹ́nu wọn. 12 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n gba Filipi gbọ́ ó ti ń wàásù ìyìnrere ti ìjọba Ọlọ́run, àti orúkọ Jesu Kristi, a bamitiisi wọn. 13 Simoni tìkára rẹ̀ gbàgbọ́ pẹ̀nígbà ti a bamitiisi rẹ̀, ó tẹ̀síwájú pẹ̀Filipi, ó wo iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ agbára ń ti ọwọ́ Filipi ṣe, ẹnu á.

14 Nígbà àwọn aposteli ó Jerusalẹmu gbọ́ àwọn ara Samaria ti gba ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n rán Peteru àti Johanu wọn. 15 Nígbà wọ́n lọ, wọ́n gbàdúrà fún wọn, wọn à gba ̀Mímọ́, 16 nítorí títí ó fi di ìgbà náà ̀Mímọ́ ì ẹnikẹ́ni nínú wọn; kìkì a bamitiisi wọn lórúkọ Jesu Olúwa ni. 17 Nígbà náà ni Peteru àti Johanu gbé ọwọ́ wọn, wọn gba ̀Mímọ́.

18 Nígbà Simoni i nípa gbígbé ọwọ́ ni ni a ń ti ọwọ́ àwọn aposteli fi ̀Mímọ́ fún ni, ó fi owó lọ̀ wọ́n, 19 ó , "fún èmi náà ni àṣẹ yìí pẹ̀, ẹnikẹ́ni èmi gbé ọwọ́ gba ̀Mímọ́."

20 Ṣùgbọ́n Peteru a lóhùn , "owó rẹ ṣègbé pẹ̀rẹ, nítorí ìwọ láti fi owó ra ̀bùn Ọlọ́run! 21 Ìwọ ni ipa tàbí ìpín nínú ̀ràn yìí, nítorí ọkàn rẹ ṣe déédé níwájú Ọlọ́run. 22 Nítorí náà ronúpìwàdà ìwà búburú rẹ yìí, ó gbàdúrà sọ́dọ̀ Ọlọ́run bóyá yóò dárí ète ọkàn rẹ ́. 23 Nítorí mo wòye , ìwọ wa nínú òróǹró ìkorò, àti ìdè ̀ṣẹ̀."

24 Nígbà náà ni Simoni dáhùn, ó , "gbàdúrà sọ́dọ̀ Olúwa fún mi, ̀kan nínú ohun ̀yin sọ ṣe mi."

25 Nígbà wọn ti jẹ́rìí, tiwọn ti sọ ̀rọ̀ Olúwa, Peteru àti Johanu padà lọ Jerusalẹmu, wọ́n wàásù ìyìnrere ni ìletò púpọ̀ ti àwọn ará Samaria.

Filipi àti ìwẹ̀Itiopia

26 Angẹli Olúwa sọ fún Filipi , "Dìde ó máa lọ ìhà gúúsù, ̀ijù, ó ti Jerusalẹmu lọ Gasa." 27 Nígbà ó dìde, ó lọ; kíyèsi, ọkùnrin kan ará Etiopia, ìwẹ̀ọlọ́púpọ̀ lọ́dọ̀ Kandake ọbabìnrin àwọn ara Etiopia, ẹni í ṣe olórí ìṣúra rẹ̀, ó ti Jerusalẹmu láti jọ́sìn, 28 Òun ń padà lọ, ó jókòó nínú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ó ń ka ìwé wòlíì Isaiah. 29 ̀fún Filipi , "Lọ ó si da ara rẹ pọ̀ mọ́ kẹ̀kẹ́ yìí."

30 Filipi si súré lọ, ó gbọ́ ti ó ń ka ìwé wòlíì Isaiah, Filipi i , "Ohun ìwọ ń yìí ha ?"

31 Ó dáhùn , "Yóò ha ṣe mi, ṣe ẹnìkan tọ́ ̀?" Ó bẹ Filipi ó gòkè , ó òun jókòó.

32 Ibi ìwé mímọ́ ìwẹ̀náà ń náà ni èyí:

"A á àgùntàn lọ fún pípa;

àti ̀dọ́-àgùntàn ń dákẹ́ níwájú olùrẹ́run rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ohun kan.

33 Nínú ìwà ìrẹ̀lẹ̀ rẹ̀ a fi ìdájọ́ òdodo dùn ún.

Ta ni ó le sọ̀rọ̀ nípa ti àwọn ìran rẹ̀?

Nítorí a gba ̀rẹ̀ kúrò ayé."

34 Ìwẹ̀náà sọ fún Filipi , "Mo bẹ̀ ́ sọ fún mi, nípa ta ni wòlíì náà ń sọ ̀rọ̀ yìí, nípa ara rẹ̀ tàbí nípa ẹlòmíràn?" 35 Filipi ya ẹnu rẹ̀, bẹ̀rẹ̀ láti ibi ìwé mímọ́ yìí, ó wàásù ìyìnrere ti Jesu fún un.

36 wọ́n ń lọ lọ́, wọ́n ibi omi kan; ìwẹ̀náà , "ó, omi nìyí. Kín ni ó mi dúró láti se ìrìbọmi?" 38 Ó pàṣẹ kẹ̀kẹ́ dúró jẹ́; àwọn méjèèjì Filipi àti ìwẹ̀sọ̀kalẹ̀ lọ sínú omi, Filipi bamitiisi rẹ̀. 39 Nígbà wọ́n jáde kúrò nínú, omi ̀Olúwa gbé Filipi lọ, ìwẹ̀i mọ́; nítorí ó ń ̀rẹ̀ lọ, ó ń yọ̀. 40 Filipi ara rẹ̀ ìlú Asotu, ó ti ń kọjá lọ, o wàásù ìyìnrere gbogbo ìlú, títí ó fi Kesarea.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-