Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Mateus 22

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 22
    Mostrando versículos 33–37 de 46

    33 22.33: Mt 7.28. Nígbà ti àwọn ènìyàn gbọ́ èyí ẹnu yà wọ́n sí ẹ̀kọ́ rẹ.

    3522.35: Lk 7.30; 11.45; 14.3.Ọ̀kan nínú wọn tí ṣe amòfin dán an wò pẹ̀lú ìbéèrè yìí.

    37 22.37: De 6.5. Jesu dáhùn pé, " ‘Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ẹ̀mí rẹ àti gbogbo inú rẹ.

  2. Jeremias 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 11–18 de 22

    11Wọ́n tọ́jú ọgbẹ́ àwọn ènìyàn migẹ́gẹ́ bí èyí tí kò jinlẹ̀."Àlàáfíà, àlàáfíà," ni wọ́n ń wí,nígbà tí kò sí àlàáfíà.

    15Àwa ń retí àlàáfíàkò sí ìre kan,tí ó wá ní ìgbà ìmúláradábí kò ṣe ìpayà nìkan.

    18Olùtùnú mi, nígbà tí ìbànújẹ́ ọkàn mi,rẹ̀wẹ̀sì nínú mi.

  3. Eclesiastes 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 2–15 de 18

    2"Asán inú asán!"Oníwàásù náà wí pé,"Asán inú asán!Gbogbo rẹ̀ asán ni."

    3Kí ni ènìyàn rí jẹ ní èrè lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ̀,lórí èyí tí ó ń ṣe wàhálà sí lábẹ́ oòrùn?

    15Ohun tí ó ti wọ́ kò le è ṣe é tọ́ mọ́,ohun tí kò sí kò le è ṣe é kà.

  4. Atos 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 13–26 de 35

    13Àwọn tí ó dìtẹ̀ yìí sì ju ogójì ènìyàn lọ.

    25Ó sì kọ ìwé kan báyìí pé,

    26Kilaudiu Lisia,sí Feliksi baálẹ̀ ọlọ́lá jùlọ,àlàáfíà.

  5. Josué 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 52–61 de 63

    52Arabu, Duma, Eṣani,

    53Janimu, Beti-Tapua, Afeka,

    61Ní aginjù:Beti-Araba, Middini, Sekaka,

  6. Marcos 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 4–35 de 35

    4Nígbà náà ni Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, "Ǹjẹ́ ó bá òfin mu ní ọjọ́ ìsinmi bóyá láti ṣe rere, tàbí láti ṣe búburú! Láti gbà ẹ̀mí là, tàbí pa á run?" Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́ láìsì.

    15àti láti lágbára láti lé àwọn ẹ̀mí Èṣù jáde.

    24Bí ìjọba kan bá yapa sí ara rẹ̀, ìjọba náà yóò wó lulẹ̀.

    35Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run, òun ni arákùnrin mi àti arábìnrin mi àti ìyá mi."

  7. Juízes 5

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 5
    Mostrando versículos 10–29 de 31

    10"Ẹ kéde rẹ̀: ẹ̀yin tí ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ funfun,ẹ̀yin tí ń jókòó lórí ẹní dáradára,àti ẹ̀yin tí ó ń rìn ní ọ̀nà.Ní ọ̀nà jíjìn sí

    16Èéṣe tí ìwọ fi dúró pẹ́ láàrín agbo àgùntànláti máa gbọ́ rè olùṣọ́-àgùntàn?Ní ipadò Reubenini ìgbèrò púpọ̀ wà.

    28"Ìyá Sisera yọjú láti ojú rèsé,ó sì kígbe, ó kígbe ní ojú rèsé ọlọ́nà pé,

    29Àwọn amòye obìnrin rẹ̀ dá a lóhùn;àní òun náà pẹ̀lú ti dá ara rẹ̀ lóhùn pé,

  8. Êxodo 11

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 11
    Mostrando versículos 1–3 de 10

    1Nísinsin yìí, Olúwa sọ fún Mose pé èmi yóò mú ààrùn kan sí i wá sí orí Farao àti ilẹ̀ Ejibiti. Lẹ́yìn náà yóò jẹ́ kí ẹ̀yin kí ó lọ kúrò níhìn-ín yìí, nígbà tí ó bá sì ṣe bẹ́ẹ̀ yóò lé yín jáde pátápátá.

    2Sọ fún àwọn ènìyàn náà pé kí tọkùnrin tobìnrin wọn béèrè fún ohun èlò fàdákà àti wúrà lọ́wọ́ aládùúgbò rẹ̀.

    3(Olúwa jẹ́ kí wọn rí ojúrere àwọn ará Ejibiti, pàápàá, Mose fúnra rẹ̀ di ènìyàn pàtàkì ní ilẹ̀ Ejibiti ní iwájú àwọn ìjòyè Farao àti ní iwájú àwọn ènìyàn pẹ̀lú).

  9. Deuteronômio 34

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 34
    Mostrando versículos 3–11 de 12

    3gúúsù àti gbogbo àfonífojì Jeriko, ìlú ọlọ́pẹ dé Soari.

    7Mose jẹ́ ẹni ọgọ́fà ọdún nígbà tí ó kú, síbẹ̀ ojú rẹ̀ kò ṣe bàìbàì bẹ́ẹ̀ ni agbára rẹ̀ kò dínkù.

    11tí ó ṣe gbogbo iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu tí Olúwa rán an láti lọ ṣe ní Ejibiti sí Farao àti sí gbogbo àwọn ìránṣẹ́ ẹ rẹ̀ àti sí gbogbo ilẹ̀ náà.

  10. 2 Coríntios 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 4–17 de 18

    4Irú ìgbẹ́kẹ̀lé yìí ni àwa ní nípasẹ̀ Kristi sọ́dọ̀ Ọlọ́run,

    8yóò ha ti rí tí iṣẹ́ ìránṣẹ́ ti ẹ̀mí kì yóò kúkú jẹ́ ògo jù?

    173.17: Isa 61.1-2.Ǹjẹ́ Olúwa ni Ẹ̀mí náà: níbi tí Ẹ̀mí Olúwa bá sì wà, níbẹ̀ ni òmìnira gbé wà.

  11. Gênesis 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 1–14 de 20

    1Sara sì pé ọmọ ọdún mẹ́tàdínláàádóje (127).

    5Àwọn ọmọ Hiti dá Abrahamu lóhùn pé,

    14Efroni sì dá Abrahamu lóhùn pé,

  12. Levítico 18

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 18
    Mostrando versículos 1–29 de 30

    1Olúwa sọ fún Mose pé:

    16 18.16: Le 20.21. " ‘Má ṣe bá aya ẹ̀gbọ́n rẹ ọkùnrin lòpọ̀ nítorí pé yóò tàbùkù ẹ̀gbọ́n rẹ.

    29" ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe ohun ìríra wọ̀nyí, kí ẹ gé irú ẹni náà kúrò láàrín àwọn ènìyàn.

  13. Ezequiel 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 2–11 de 11

    2Lójú ẹsẹ̀ ni ọkùnrin mẹ́fà jáde láti ẹnu-ọ̀nà òkè tó kọjú sí ìhà àríwá, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà olóró lọ́wọ́ wọn. Ọkùnrin kan tó wọ aṣọ funfun gbòò wa láàrín wọn, pẹ̀lú ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀. Gbogbo wọn sì dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ idẹ.

    3Ògo Ọlọ́run Israẹli sì gòkè kúrò lórí kérúbù, níbi tó wà tẹ́lẹ̀ lọ sí ibi ìloro tẹmpili. Nígbà náà ni Olúwa pe ọkùnrin tó wọ aṣọ funfun náà tí ó sì ní ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.

    11Ọkùnrin tí ó wọ aṣọ ọ̀gbọ̀, tí ó ní ìwo tàdáwà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ròyìn pé, "Mo ti ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti pàṣẹ fún mi."

  14. 1 Crônicas 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 12–37 de 55

    12Boasi baba Obediàti Obedi baba Jese.

    15ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemuàti ẹlẹ́ẹ̀keje Dafidi.

    37Sabadi ni baba Eflali,Eflali jẹ́ baba Obedi,

  15. 1 Coríntios 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 18–32 de 58

    1815.18: 1Tẹ 4.16.Ǹjẹ́ àwọn pẹ̀lú tí ó sùn nínú Kristi ṣègbé.

    26Ikú ní ọ̀tá ìkẹyìn tí a ó parun.

    3215.32: 2Kọ 8–9; Isa 22.13.Kí a wí bí ènìyàn, bí mo bá ẹranko jà ní Efesu, àǹfààní kín ni ó jẹ́ fún mi? Bí àwọn òkú kò bá jíǹde,"Ẹ jẹ́ kí a máa jẹ, kí á máa mú;nítorí ní ọlá ni àwa ó kú."

  16. Cânticos 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 3–9 de 13

    3Ọmú rẹ rí bí abo egbin méjìtí wọ́n jẹ́ ìbejì àgbọ̀nrín.

    6Báwo ni ẹwà rẹ ti pọ̀ tóbáwo ni o sì ti dára tó ìwọ olùfẹ́ mi nínú ìfẹ́?

    9Àti ìfẹnukonu rẹ rí bí ọtí wáìnì tí ó dára jùlọ.Olólùfẹ́Tí ó kúnná tí ó sì dùn,tí ń mú kí ètè àwọn tí ó sùn kí ó sọ̀rọ̀.

  17. Provérbios 16

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 16
    Mostrando versículos 23–30 de 33

    23Ọkàn ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ṣọ́ ẹnu rẹ̀ètè rẹ̀ sì ń mú kí ẹ̀kọ́ dàgbà.

    27Ènìyàn búburú ń pèteọ̀rọ̀ rẹ̀ sì dàbí i iná tí ń jóni.

    30Ẹni tí ń ṣẹ́jú ń pètekéte;ẹni tí ó ṣu ẹnu jọ ń pète aburú.

  18. Efésios 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 12–17 de 21

    12Nínú ẹni tí àwa ní ìgboyà, àti ọ̀nà pẹ̀lú ìgbẹ́kẹ̀lé nípa ìgbàgbọ́ wa nínú rẹ̀.

    15Orúkọ ẹni tí a fi ń pe gbogbo ìdílé tí ń bẹ ni ọ̀run àti ní ayé.

    17Kí Kristi lè máa gbé inú ọkàn yín nípa ìgbàgbọ́; pé bí ẹ ti ń fi gbòǹgbò múlẹ̀ tí ẹ sì ń fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ nínú ìfẹ́;

  19. Salmos 51

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 51
    Mostrando versículos 2–17 de 19

    2Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi nù kúròkí o sì wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi!

    10Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọ́run,kí o sì tún ẹ̀mí dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.

    17Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.

  20. Números 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 11–44 de 51

    11 3.11-13: Nu 3.45; 8.18. Olúwa tún sọ fún Mose pé,

    33Ti Merari ni ìran Mahili àti Muṣi, àwọn ni ìran Merari.

    36Àwọn ìran Merari ni a yàn fún títọ́jú àwọn rémù àgọ́, ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, òpó rẹ̀, ihò òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò tó jẹ mọ́ lílò wọn.

    44Olúwa tún sọ fún Mose pé,

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo