Publicidade

Eclesiastes 2

Ìgbádùn

1 Mo nínú ọkàn mi, "nísinsin yìí, èmi yóò dán pẹ̀ìgbádùn láti ṣe àwárí ohun ó dára." Ṣùgbọ́n eléyìí náà jásí asán. 2 "Mo fún ̀rín òmùgọ̀ ni. Àti fún ìre-ayọ̀ ni ó ń ṣe?" 3 Mo tiraka láti dun ara mi nínú pẹ̀ọtí wáìnì, àti láti fi ọwọ́ òmùgọ̀—ọkàn mi ń tọ́ mi pẹ̀ọgbọ́n. Mo fẹ́ wo ohun ó yẹ ṣíṣe fún ènìyàn abẹ́ ̀run ìwọ̀nba ọjọ́ ayé rẹ̀.

4 Mo ṣe àwọn iṣẹ́ ńlá ńlá. Mo kọ́ ilé púpọ̀ fún ara mi, mo gbin ọgbà àjàrà púpọ̀. 5 Mo ṣe ọgbà àti àgbàlá, mo gbin onírúurú igi eléso inú wọn. 6 Mo gbẹ́ adágún láti máa bu omi rin àwọn igi ó ń jáde nínú ọgbà. 7 Mo ra àwọn ẹrú ọkùnrin àti àwọn ẹrú obìnrin, mo tún àwọn ẹrú mìíràn a ilé mi. Mo tún ẹran ̀sìn ju ẹnikẹ́ni Jerusalẹmu lọ. 8 Mo fàdákà àti wúrà jọ fún ara mi àti àwọn ohun ìṣúra ti ọba àti ìgbèríko. Mo àwọn akọrin ọkùnrin àti obìnrin, àti dídùn inú ọmọ ènìyàn, aya àti obìnrin púpọ̀. 9 Mo di ẹni ńlá ju ẹnikẹ́ni ó Jerusalẹmu ṣáájú mi. Nínú gbogbo èyí, ọgbọ́n mi fi sílẹ̀.

10 Èmi jẹ́ ojú mi ṣe aláìrí ohun ó ń fẹ́.

N jẹ́ ọkàn mi ó ṣe aláìní ìgbádùn.

Ọkàn mi yọ̀ nínú gbogbo iṣẹ́ mi,

èyí ni èrè fún gbogbo wàhálà mi.

11 Síbẹ̀, nígbà mo wo gbogbo ohun ọwọ́ mi ti ṣe

àti ohun mo ti ṣe wàhálà láti :

gbogbo rẹ̀, asán ni. Ó dàbí ẹni

gbìyànjú àti afẹ́fẹ́, èrè kan abẹ́ oòrùn;

ọgbọ́n àti òmùgọ̀, asán ni.

12 Nígbà náà ni mo tún bẹ̀rẹ̀ ọgbọ́n,

àti ìsínwín àti àìgbọ́n

ni ọba ó jẹ lẹ́yìn ọba kan le è ṣe

ju èyí ọba ìṣáájú ti ṣe lọ.

13 Mo ri ọgbọ́n dára ju òmùgọ̀

gẹ́gẹ́ ìmọ́lẹ̀ ti dára ju òkùnkùn lọ.

14 Ojú ọlọ́gbọ́n ń bẹ lágbárí rẹ̀,

nígbà aṣiwèrè ń rìn nínú òkùnkùn,

ṣùgbọ́n mo padà mọ̀

ìpín kan náà ni ó ń dúró de ìsọ̀àwọn ènìyàn méjèèjì.

15 Nígbà náà ni mo nínú ọkàn ,

"Irú ìpín òmùgọ̀ yóò èmi náà pẹ̀

ni ohun mo jẹ èrè nípa ọgbọ́n?"

Mo sọ nínú ọkàn mi ,

"Asán ni eléyìí pẹ̀."

16 Nítorí ọlọ́gbọ́n ènìyàn, gẹ́gẹ́ i òmùgọ̀, a yóò rántí rẹ̀ fún ìgbà pípẹ́;

gbogbo wọn ni yóò di ohun ìgbàgbé ọjọ́ ń bọ̀.

Ikú ó pa aṣiwèrè náà ni yóò pa ọlọ́gbọ́n ènìyàn.

Asán ni iṣẹ́ ṣíṣe

17 Nítorí náà, mo kórìíra ìwàláàyè, nítorí iṣẹ́ wọn ń ṣe abẹ́ oòrùn ti ìdààmú mi. Gbogbo rẹ̀ asán ni, ó dàbí ẹni ń gbìyànjú àti afẹ́fẹ́ ni. 18 Mo kórìíra gbogbo ohun mo ti ṣiṣẹ́ fún abẹ́ oòrùn, nítorí mo láti fi wọ́n sílẹ̀ fún ẹni ó lẹ́yìn mi ni. 19 Ta ni ó mọ̀ bóyá ọlọ́gbọ́n ènìyàn ni yóò jẹ́ tàbí aṣiwèrè? Síbẹ̀ yóò láti ṣe àkóso lórí gbogbo iṣẹ́ mo ṣe yìí pẹ̀. 20 Nítorí náà, ọkàn mi bẹ̀rẹ̀ kábámọ̀ lórí gbogbo àìsimi iṣẹ́ ṣíṣe mi abẹ́ oòrùn. 21 Nítorí ènìyàn le è ṣe iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀ọgbọ́n, òye àti ìmọ̀ abẹ́ oòrùn, ó ti kọ́ ṣe iṣẹ́ fúnra rẹ̀. Asán ni eléyìí pẹ̀àti àdánù ńlá. 22 ni ohun ènìyàn gbà fún gbogbo wàhálà àti ìpọ́njú ó fi ṣiṣẹ́ lábẹ́ oòrùn? 23 Gbogbo ọjọ́ rẹ, iṣẹ́ rẹ kún fún ìrora, àti ìbànújẹ́, kódà ọkàn rẹ̀ í ìsinmi alẹ́. Asán ni eléyìí pẹ̀.

24 Ènìyàn le è ṣe ohunkóhun ó dára ó jẹ ó mu, ó ìtẹ́lọ́rùn nínú iṣẹ́ rẹ̀. Mo eléyìí pẹ̀láti ọwọ́ Ọlọ́run. 25 Nítorí láìsí òun, ta ni ó le jẹ tàbí ó mọ adùn? 26 Fún ẹni ó tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn ni Ọlọ́run yóò fún ọgbọ́n, ìmọ̀ àti ìdùnnú, ṣùgbọ́n fún ẹni dẹ́ṣẹ̀, Ó fún un iṣẹ́ láti ṣà àti láti ohun ìní pamọ́ ó fi fún ẹni ó tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn. Eléyìí pẹ̀, asán ni, ó dàbí ẹni gbìyànjú àti afẹ́fẹ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-